Browsing Category
ÌRÒYÌN YÀJÓ-YÀJÓ
This is a category for TRENDING NOW
Agbófinró ìpínlẹ̀ Adamawa, Àwọn Akọ̀ròyìn fọwọ́sowọ́pọ̀ láti túnbọ̀ gbé ètò ààbò ró
Lára ìgbésẹ̀ láti ṣe ìgbélárugẹ ìfọwọ́sowọ́pọ̀ láàrin Agbófinró àti Akọ̀ròyìn, Kọmíṣọ́nà fún Agbófinró, ti ikọ̀ ìpínlẹ̀ Adamawa, CP Dankombo Morris, ti kí aṣojú láti inú ẹgbẹ́ àwọn Akọ̀ròyìn (NUJ), ikọ̀ ti…
Ìpínlẹ̀ Oyo: Àwọn Amòfin gbé ìgbésẹ̀ láti fagilé lílo ẹ̀rọ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ alágbéká…
Ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin ti Ìpínlẹ̀ Oyo ti paá láṣẹ fún ìgbìmọ̀ ètò Ẹ̀kọ́ (Àkọ́bẹ̀rẹ̀ àti Gíga) láti ṣèjíròrò pẹ̀lú àwọn tó níí ṣe àti láti ṣètò ọ̀nà láti gbé ìfagilé lílo ẹ̀rọ ìbaraẹnisọ̀rọ̀ alágbéká ní…
Ẹgbẹ Alátakò pàtàkì Tanzania kò ní ẹ̀tọ́ sí Ìdìbò
Ẹgbẹ Alátakò pàtàkì Tanzania, CHADEMA, kò ní ní àǹfààní láti kópa nínú ìdìbò gbogbogbòò tó ń bọ́ lọ́nà, àgbà òṣìṣẹ́ ìgbìmọ̀ olómìnira tí ń mójútó ètò ìdìbò lórílẹ̀-èdè ló kéde rẹ̀ lọ́jọ́…
Gombe: Agbófinró bẹ̀rẹ̀ ètò ìwòsàn ọ̀fẹ́
Lára àwọn ètò láti ṣàmì ayẹyẹ Àyájọ́ Àkọ́kọ́ irú ẹ̀ ti Agbófinró ní ìpínlẹ̀ Gombe, Adarí Agbófinró ti pèsè ètò ìwòsàn ọ̀fẹ́ láti ṣàtúnṣe lórí ìlera àwọn ará ìlú àti láti túnbọ̀ fìdí àjọṣepọ̀…
CAF ṣèdárò pẹ̀lú ẹbí Christian Chukwu
Ààrẹ Ìgbìmọ̀ Ẹgbẹ́ Agbábọ́ọ́lù Adúláwọ̀ (CAF), Dókítà Patrice Motsepe, ti ṣèdáro pẹ̀lú ẹbí Christian Chukwu, ènìyàn pàtàkì nínú eré bọ́ọ́lù Nàìjíríà àti ti Adúláwọ̀.
Dokita Motsepe fi ẹdun ọkan rẹ han…
Ẹgbẹ́ àwọn ọmọ akẹ́kọ̀ọ́ Nàìjíríà lókè òkun yan àwọn aláṣẹ tuntun
Ẹgbẹ́ àwọn ọmọ akẹ́kọ̀ọ́ Nàìjíríà lápapọ̀ lókè òkun ti yan àwọn aláṣẹ tuntun tó pinnu láti jẹ́ aṣojú rere fún Nàìjíríà.
Aarẹ ẹgbẹ naa Ọgbẹni Juwon Fayomi, ṣe ipinnu yii nibi ayẹyẹ ifilọlẹ ati Idanilẹkọ fun gbogbogboo…
Ààrẹ Tinubu ṣèdárò ikú ògbóhùntarìgì agbábọ́ọ́lù Nàìjíríà, Christian Chukwu
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti ṣèdárò pẹ̀lú ẹbí, ọ̀rẹ́ àti àwọn alájọṣepọ̀ ògbóhùntarìgì agbábọ́ọ́lù Nàìjíríà Christian Chukwu, tí ó di olóògbé ní ọjọ́ Àbámẹ́ta ní ọmọ ọdún mẹ́rìnlé-láàdọ́rin.
Nigba ti o n…
DR Congo: Omíyalé Agbára Ya Gboro Pa Mẹ́tàlélọ́gbọ̀n Ènìyàn
Omi àgbàrá Òjò ti pa Mẹ́tàlélọ́gbọ̀n olùgbé, ó sì tún gbé ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilé lọ ni Kinshasa ti ṣe Olú ìlú Congo.
Bí Mínísítà òde orílẹ̀-èdè ṣe sọ, àwọn tó lùgbàdí ọ̀ràn náà ni àgbàrá Òjò àrọ̀rọ̀rọ̀dá sekúpa, tó sì gbélé lọ ti…
Àwọn ọmọ ogun ojú omi Nàìjíríà pèsè ètò ìwòsàn ọ̀fẹ́ ní Bayelsa
Àwọn ọmọ ogun ojú omi Nàìjíríà SOROH, NNS SOROH, ti pèsè ètò ìwòsàn ọ̀fẹ́ fún àwọn aládùúgbò Tombia tó ju ẹgbẹ̀rún méjì lọ, ní ìjọba ìbílẹ̀ Yenagoa, ní́ ìpínlẹ̀ Bayelsa , Gusu Nàìjíríà.
Ajagun…
Ukachukwu yege láti kópa nínú ìbò Gómìnà APC fún Anambra
Ọmọ Ọba Nicholas Ukachukwu ti jáwé olúborí bíl olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC) fún ìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra tí ń bọ̀ lọ́nà ní oṣù kọkànlá ọdún 2025.
Ukachukwu jawe olubori nigba ti o yege…