Browsing Category
ÌRÒYÌN YÀJÓ-YÀJÓ
This is a category for TRENDING NOW
NTDs: Adarí gbogbogbòò NITR rọ àwọn tó nííṣe láti ṣàtúnṣe lórí ìnáwó
Adarí gbogbogbòò ti ilé iṣẹ́ tí ń ṣe ìwáádí Trypanosomiasis (NITR), Joachim Ajakaiye ti rọ ìjọba àpapọ̀ àti àwọn tó nííṣe láti wá owó ṣètò ìjàfita fita Nàìjíríà láti gbógunti àwọn ààrùn inú igbó tí wọ́n…
Kọmíṣọ́nà fún ètò ìlera Anambra pinnu ìtọ́jú alábọ́ọ́dè, tósì tún múná dóko
Kọmíṣọ́nà fún ètò ìlera ní ìpínlẹ̀ Anambra, Dokita Afam Obidike, túnbọ̀ fìdí ìpinnu ìjọba ìpínlẹ̀ múlẹ̀ lórí ìpèsè ètò ìtọ́jú tó wà lárọwọ́tó, tí owó rẹ̀ kò sì tún ní jara lọ fún àwọn ará ìlú níbi…
Àwọn alájọṣepọ̀ ààrẹ Benin fi ẹ̀wọ̀n ogún ọdún gbára lórí ìgbèrò ìfipá gbàjọba
Àwọn arákùnrin méjì kan tí wọ́n súnmọ́ ààrẹ orílẹ̀ - èdè Benin, ti fi ẹ̀wọ̀n ogún ọdún gbára lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n mú wọn lọ́dún tó kọjá lórí ìgbèrò ìfipá gbàjọba lórílẹ̀ èdè náà.
Ile Ẹjọ ti n risi ẹṣẹ…
Ààrẹ Tinubu yan Abba Aliyu ní Adarí Ìṣàkóso REA
Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu ti yan Abba Abubakar Aliyu ní Adarí Ìṣàkóso fún Ilé Iṣẹ́ tí ń rísí ìṣètò Iná Mọ̀nàmọ́ná ní Ìgbèríko (REA).
Alaye kan ti agbenusọ fun aarẹ, Ọgbẹni Bayọ Ọnanuga buwọlu ni ọjọ Jimọh, sọ pe yiyan…
Ààrẹ Tinubu àti ìjọ Tijaniyya gbàdúrà fún ìrọ̀rùn ní Nàìjíríà
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu kírun Jímọ̀h pẹ̀lú àwọn adarí ìjọ Mùsùlùmí Tijaniyya tí ó ṣe àbẹ̀wò sí i,ní ilé ìjọba, ní Abuja, tí Khalifa Mahiy Sheikh Ibrahim Inyass, ṣadarí.
Lẹyin irun naa, aarẹ ṣe ipade apapọ adura…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Kẹ́dùn Ikú Ẹ̀gbọ́n Rẹ̀, Onímọ̀ Ẹ̀rọ Sunday Makinde
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti kẹ́dùn ikú ẹ̀gbọ́n rẹ̀, Onímọ̀ Ẹ̀rọ Sunday Makinde.
Àtẹ̀jade ti Oludamọran fún Gómìnà lórí ìròyìn, Suleimon Olanrewaju fi síta fún àwọn oníròyìn ní ìlú Ìbàdàn tíì ṣe Olú ìlú Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, ni Ẹkùn…
Àwọn lọ́balọ́ba ìpinlẹ̀ Ọ̀ṣun gbóríyìn fún Aṣòfin Bamidele Salam
Àwọn lọ́balọ́ba tó ju ọgọ́rùn ún lọ láti ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́rin ní Àríwá Ẹdẹ, Gusu Ẹdẹ, Egbedore, àti agbègbè ìjọba àpapọ̀ Èjìgbò ti ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun ti gbóríyìn fún Ọ̀gbẹ́ni Bamidele Salam.
Wọ́n rí ipa pàtàkì tó…
2027: Míní́sítà fún Iṣẹ́ buwọ́lu èròńgbà Gómìnà Nwifuru lóríi sáà kejì
Gómìnà tó ṣẹ̀ṣẹ̀ kúrò ní ìpínlẹ̀ Ebonyi tí ó jẹ́ Mínísítà fún ètò ìṣẹ́ lọ́wọ́ báyìí, Sẹ́nétọ̀ David Umahi ti sọ pé òun ti tẹ́wọ́gba àtúnyàn Gómìnà Francis Nwifuru fún sáà kejì lórí oyè nínú ìbò…
Gómìnà Kwara pàdánù Ọ̀gá Àgbà fún àwọn òṣìṣẹ́ AbdulKadir Mahe
Ọ̀gá Àgbà fún àwọn òṣìṣẹ́ (CoS) fún Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara, Ọmọọba AbdulKadir Mahe, ti jẹ́pè olúwa. Ó jẹ́pè olúwa ní àárọ kùtù ọjọ́ Àbámẹ́ta.
Ọ̀gá àgbà Akọ̀wé sí Gómìnà, Mallam Rafiu Ajakaye, ní ó kéde…
Igbákejì Ààrẹ Shettima kẹ́dùn pẹ̀lú Gómìnà Ìpínlẹ̀ Jigawa lórí Àjálù méjì tó…
Ààrẹ Bọla Tinubu ti yan àwọn asojú kan tí Igbákejì Ààrẹ Kashim Shettima ṣadarí, láti ṣe àbẹ̀wò ìkẹ́dùn sí Gómìnà àti àwọn ènìyàn Jigawa lórí ikú ìyá àti ọmọkùnrin Gómìnà ìpínlẹ̀ náà, Alhaji Umar…