Browsing Category
ÌRÒYÌN ÈTÒ Ọ̀GBÌN
Ẹgbẹ́ CADEF Pe Fún Ìdíwó Lórí Ríra Ounjẹ Lọ́jà
Ẹgbẹ́ tó n mójú tó ọ̀rọ̀ àwọn káràkátà (CADEF) ti tẹnumọ́ wí pé kí a wọ ṣe fun ara wa nípa ìdíwó lórí ọja oúnjẹ.
Ẹgbẹ́ yìí sọ èyí di mímọ nínú atejade kan láti ọwọ́ adari ẹgbẹ́ náà ọ̀mọ̀wé Chiso Okafkor ni ọjọ́ ìṣẹgun ni ilu Eko.…
Gómìnà ìpínlẹ̀ Sòkòtò Tẹnumọ́ Ìdí Tí o Fí Ye ki Wọn Da Àgbè Tó Dágájírá Mọ.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Sòkòtò, Ọgbẹni Ahmad Aliyu tẹnumọ́ anfààní to wa nínú ki ènìyàn ní àgbè tó Dágájírá láti se ètò ohun ọ̀gbin pẹ̀lú ìmọ̀ láti mú ìdàgbàsókè bá ètò ọ̀gbìn.
Ó sọ èyí di mímọ nígbà tí o ṣe àbẹ̀wò sí ilé iṣé ìjọba fún ètò ọ̀gbìn…
Gómìnà ìpínlẹ̀ Sòkòtò Tẹnumọ́ Ìdí Pàtàkì Tí o Ye ki Wọn Da Àgbè Tó Dágájírá Mọ.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Sòkòtò, Ọgbẹni Ahmad Aliyu tẹnumọ́ anfààní to wa nínú ki ènìyàn ní àgbè tó Dágájírá láti se ètò ohun ọ̀gbin pẹ̀lú ìmọ̀ láti mú ìdàgbàsókè bá ètò ọ̀gbìn.
Ó sọ èyí di mímọ nígbà tí o ṣe àbẹ̀wò sí ilé iṣé ìjọba fún ètò ọ̀gbìn…
Àjọ AFAN: Ìpínlẹ̀ Enugu Yóò Gbádùn Ìpèsè Ẹ̀gẹ́ Yanturu
Alága àjọ , All Farmers Association of Nigeria (AFAN) ni ìpínlẹ̀ Enugu, ọ̀gbẹ́ni Romanus Eze, ti sọ pé ìrètí wà fún ìpèsè ẹ̀gẹ́ yanturu ninu ọdún yìí.
Ọgbẹni Eze sọ eyi níbi ìfòròwánilẹ́nuwò ni ilu Enugu ni ọjọ Ọjọ́rú. O sọ pe ọpọ…
Àwọn Onímọ̀ Nípa Ètò Ọ̀gbìn Yóò Rí Dájú Wí Pé Ìdàgbàsókè Bá Ètò Ọ̀gbìn – Ọ̀gá Àgbà ARCN
Ilé iṣé Ìwádìí nípa ọ̀gbìnni Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ARCN sọ wí pé àwọn yóò sá gbogbo ipa àwọn láti rí wí pé ètò ògbìn ni ilọsiwaju pẹ̀lú ìbámu labẹ ijoba lati ní anito oúnjẹ ni ilé.
Akọ̀wé fun ẹgbẹ́ ARCN Garba Sharubutu ni o sọ èyí di mímọ…
Sí Ṣe Ọ̀gbìn Eso Kiwi Ni Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Iṣẹ́ ọ̀gbìn èso Kiwi jẹ ohun ọgbin ìpìlẹ̀ láti ìgbà ayé wa.
Èso yìí jẹ́ èso ti wa láti Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà China, nígbà tí ọ di akoko kàn wọn mú Ọ̀gbìn èso yìí ló sì Orílẹ̀-èdè Zealand, titi won fi mú dè Orile-èdè Nàìjíríà nipasẹ…
Àwọn Tí Ó Ń Fi Owó Ṣe Ìrànlọ́wọ́ Fún Àwọn Ènìyàn Ṣe Ìrànlọ́wọ́ Fún Àwọn Àgbè Ni Ìpínlẹ̀ Enugu.
Ọgá àgbà pátápátá fún ilẹ iṣé Paschal -Rico, Olóyè Pascal Aneke àti Ọ̀gbẹni Sunday Ozokolo láti Orílẹ̀-èdè Switzerland ni ọjọ́ ìsinmi Pin àwọn ohùn èlò ìrànlọ́wọ́ fún àwọn àgbẹ̀ ìgbèríko ni ìjọba ìbílẹ̀ Ezeagu ni Ìpínlẹ̀ Enugu.
Àwọn…
Gómìnà ìpínlẹ̀ Borno Sọ Wí pé Ilẹ̀ Ẹ́ẹ̀kà Méje Ti Wà Nílẹ̀ Fún Ètò Ọ̀gbìn.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Borno Babagana Umara Zulum, ti ṣe àfihàn ilẹ̀ ẹ́ẹ̀kà méje fún ètò ọ̀gbìn labẹ ìjọba rẹ.
Ó ní ètò yìí wà fún àtìlẹ́yìn ìjọba Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu lórí ìrètí nlá fún Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ó sọ èyí di mímọ̀ ni Mafa ni…
Àsìkò Ọ̀gbẹ Ilé: Mínísítà Ṣe Àyẹ̀wò Ounjẹ Wheat.
Mínísítà fún ètò ọ̀gbìn àti ààbò fún oúnjẹ (FMAFS) Ṣẹ́nitọ̀ Abubakar Iyari àti Mínísítà fún ìpínlẹ̀, Ṣẹ́nitọ̀ Aliyu Sani Abdullahi ṣe ìbẹ̀wò sí ọ̀gbìn oúnjẹ whaet ni ọjọ́ keje oṣù kọkànláọjọ́ fun ètò ọ̀gbìn ti ijoba àpapọ gbé kalẹ.
Ètò…
Àwọn tó nííṣe ṣe àyẹ́síi ìgbé ayé àwọn àgbẹ̀
Owó káríayé fún ìdàgbàsókè ètò ọ̀gbìn, IFAD-Ètò ìrànlọ́wọ́ àpapọ̀ iyì fún ìdàgbàsókè, VCDP, ti sọ pé ọdún mẹ́sàn án ti òhun ti wà ní ìpínlẹ̀ Ebonyi, Gúsù iwọ̀ oòrùn Nàìjíríà, ti ran ìgbé ayé…