Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ
This is a category for business news
Ẹka Ìjọba Tí Ó Ń Darí Ìgbòkègbodò Ọkọ̀ Òfurufú Ní Adarí Tuntun
Arábìnrin Olubunmi Kuku ni wọ́n yàn sípò gẹ́gẹ́ bí adarí tuntun ní ẹka ìjọba tí ó wà fún ìgbòkègbodò ọkọ̀ òfurufú. Ó fi àrídájú hàn sí àwọn tí ọ̀rọ̀ kàn ní ẹka ìjọba náà wípé ìsàkóso Òun yóò…
LCCI Yóò Gbàníyànjú Ìpolongo Ìmúríyá
Ìgbákejì Ààrẹ túntún tí Ilé-ìgbìmọ̀ òkòwò àtí Ìṣòwò tí Ìpínlẹ̀ Èkó, Layo Okeowo, tí ṣàlàyé pé àwọn Ìgbìmọ̀ Aláṣẹ túntún náà yóò dojukọ ìpolongo tó dá lórí móríyá.
Okeowo ló sọ èyí dì mímọ̀ lásìkò tí wọ́n yàn àwọn aláṣẹ túntún LCCI ní…
Ẹgbẹ́ Àwọn Olùdókoòwò Àti Àmójútó Ilé Iṣẹ́ Ẹka Ti Abuja Ní Adarí Tuntun
Wọ́n ti yan Emeka Obegolu gẹ́gẹ́ bí adaŕi ẹgbẹ́ olùdókoòwò àti àmójútó Ilé Iṣẹ́, ẹka tí Abuja
Ọgbẹ́ni Obegolu, ẹni tí wọ́n yànsípò níbi ìpàdé ọlọ́dọọdún olọ́dún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n irú rẹ̀ ní ìlú Abuja sọ…
Àjọ Tí Ó Ń Pèsè Omi Ní Ìlú Abuja Pa Ọ̀pọ̀lọpọ̀ Owó Wọlé Fún Ìjọba Ní Ọdún 2023
Àjọ tí ó ń pèsè omi tí ó se é bùmu-bùwẹ̀ ti pa owó tí ó tó bílíọ̀nù mẹ́ta lé díẹ̀ láàrin osù kíní sí osù kọkànlá
Adelé Alákòóso Àpapọ̀ fún àjọ náà, Ọ̀gbẹ́ni Daniel Salka ni ó síṣọ lójú…
Ìròyìn Ayọ̀: Ìrètí Wà Pé Ọ̀wọ́ngógó Owó Ọjà Àti Ìpààrọ̀ Owó Ilẹ̀ Òkèèrè Tí Ó…
Ilé Ìfowópamọ́ Àpapọ̀ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti sọ pé ọ̀wọ́ngógó owó ọjà àti ìpààrọ̀ owó ilẹ̀ òkèèrè tí ó ti lọ sókè ni ìrètí wà pé yóò wálẹ̀ ní ọdún 2024
Gómìnà ilé ìfowópamọ́…
Àwọn Ilé Iṣé Nlá Nlá Pe Ìjọba Ìpínlẹ̀ Eko Láti Dẹ́kun Ìwà ìbàjẹ́ Láti Ọwọ́ Àwọn Oníṣẹ́ Láabi.
Ẹgbẹ́ àwọn ilé iṣé nla nlá ti Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti rawọ ẹ̀bẹ̀ sí ìjọba ìpínlẹ̀ Eko lati Dẹkun ìwà ìbàjẹ́ láti ọwọ́ àwọn láabi.
Wọn ní ìwà ìbàjẹ́ yìí n pa àwọn lára púpọ̀ nítorí o ṣe àkóbá nla fún dukia àti ilé iṣé.
Ọ̀gá Àgbà…
Ilé Ìfowópamọ́ Àpapọ̀ Ti Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ti Pàṣẹ kíkójáde, Gbígbà Owó Àtijọ́…
Lójúnà àti tẹ̀lé ìdájọ́ Ilé Ẹjọ́ Àpapọ̀ ti Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ó wáyé ní Ọjọ́rú, ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n osù kọkànlá níbi tí ilé ẹjọ́ ti gba ìrawọ́ ẹ̀bẹ̀ amòfin àgbà wọlé, èyí tí ó pè fún…
Ilé Ẹjọ́ Gíga Ti Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ti Fi Àyè Gba Níná Owó Náírà Àtijọ́ Àti…
Ilé Ẹjọ́ Gíga Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti fi àyè gba níná owó náírà tuntun àti ti àtijọ́ ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà èyí tí ó fagilé gbèdéke ọjọ́ kọkànlélọ́gbọ̀n osù kejìlá ọdún 2023 èyí tí ó ti wà…
Ààrẹ Bọla Tinubu Tẹ́ Pẹpẹ Ètò Ìsúná Sí Iwájú Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin
Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu ti tẹ́ pẹpẹ ètò ìsúná tí ó tó tírílíọ̀nù méjìdínlọ́gbọ̀n sí iwájú ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin fún ọdún 2024. Ó sàlàyé pé ìjọba yóò sé àmúsẹ ètò ìsúnná náà láti mú ìgbòòrò bá…
Ìdàgbàsókè Yóò Débá Ìgbòkè-gbodò Ọkọ̀ Òfurufú Ní Cross River- Bassey Otu
Gòmìnà Ìpínlẹ̀ Cross River, Bassey Otu ti parí ètò láti mú ìgbòòrò bá ìgbòkè-gbodò ọkọ̀ òfurufú, nígbà tí ó gba ilé iṣẹ́ Aero láyè lati bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ní ìlú Calabar
Gómìnà Otu tún gbé ìgbésẹ̀…