Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ
This is a category for business news
Iṣẹ́ àgbẹ̀ niṣẹ́ ilẹ̀ wa
Ìjọba àpapọ̀ ti sọ pé òun yóò tẹ̀síwájú láti mú iṣé àgbẹ̀ rọrùn ní ṣíṣe fún ìdàgbàsókè iṣẹ́-ọ̀gbìn àti ẹ̀ka ọjà.
Akọwe gbogbogboo, ile-iṣẹ ijọba apapọ to n mojuto iṣowo,kara-kata ati idokowo, Dokita Evelyn Ngige,…
Ìpàtẹ ọjà Kwara : Gómìnà Abdulrazaq Ṣèlérí Àtìlẹyìn Fún Àwọn oníṣòwò
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kwara, AbdulRahman AbdulRazaq ní ìparí ọ̀sẹ̀ ti ṣe ìlérí àtìlẹ́yìn nígbà gbogbo fún àwọn ọ̀dọ́, pẹ̀lú àwọn tí ó ní ipa nínú àwọn ilé-iṣẹ́ orísirísi.
Gomina naa sọrọ ni Ilorin, olu-ilu ipinlẹ…
Iná tó se déédé ṣe pàtàkì fún ìdàgbàsókè ọrọ̀-ajé
Minisita Ipinlẹ fun Awọn orisun Epo ilẹ, Timipre Sylva, ti sọ pe orilẹ-ede Naijiria nilo ina ti owo rẹ ko jara lọ,to fọkanbalẹ, ti o si ṣe deede lati gbogunti ipọnju ina ati fun idagbasoke ọrọ-aje.
O sọ eyi nibi ipade ọrọ orisun Adanida…
Ìbò 2023 : Ojú lalákàn fi ń ṣọ́rí
Ìpilẹ̀ṣẹ̀ ìdìbò gbogbogbòò ọdún 2023 ní Nàìjíríà ti jẹ́ kí àwọn olùdókòwò ṣọ́ra nípa ìgbésẹ̀ ìdókò-wò.
Gẹgẹ bi Aarẹ Chartered Institute of Stockbrokers ni Naijiria, Ọgbẹni Wole Adeọṣun, ti o sọ pe awọn…
Ọmọ ẹgbẹ́ Ilé-Aṣòfin Nàìjíríà Pẹ̀lú Àjọṣèpọ̀ àjọ tí kìí ṣe tìjọba gbìmọ̀ Láti fún…
Ọ̀kan lára àwọn ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣojú-ṣòfin, Alhaji Balarabe Salame (APC-Sókótó) ti ṣe agbátẹrù ìdánilẹ́ẹ̀kọ́ fún àwọn ọ̀dọ́ mẹ́tà-lé-lójì-dín-lẹ́gbẹ̀ta lórí orísirísi ètò ìmò ìṣe ní Sókótó.
Salame, ọmọ…
Àwọn ènìyàn wá wọ̀rọ̀kọ̀ fi ṣàdá lórí ọ̀wọ́n gógóo gáásì ìdáná … Àwọn…
Lílo Gáàsì ìdáná Àdáyébá (LPG) ti lọ sílẹ̀ jákèjádò orílẹ̀-èdè.
Aarẹ, Ẹgbẹ oni Gaasi ni Naijiria, Ed Ubong, sọ lakoko apejọ kan ni Ilu Eko, pe gaasi lilo ọdọọdun orilẹ-ede lọwọlọwọ bayii jẹ 1.3mn ati 1.5mn mẹtiriki…
FAO: Iye Owó orí Oúnjẹ Àgbáyé wálẹ̀ nínú Oṣù Kẹrin
Àjọ àgbáyé fún Oúnjẹ àti Iṣẹ́-ọ̀gbìn, (FAO) sọ pé àwọn ìdíyelé ọjà àgbáyé wálẹ̀ nínú Oṣù Kẹrin lẹ́yìn tí ọ̀wọ́n gógó gorí ọjà ní oṣù tí ó kọjá, èyí tí ó jẹ́ ìdarí nípasẹ̀ ìdínkù ìwọ̀ntúnwọ̀nsì…
Ilé ìgbìmọ̀ Aṣojú Ṣèwádìí bí epo ilẹ̀ àti Gáásì fi gbówólérí
Ilé-ìgbìmọ̀ Aṣojú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ti kàn án nípá fún ìgbìmọ̀ rẹ̀ lórí Àwọn orísun Epo ilẹ̀ àti ọ̀rọ̀ Gáásì láti ṣe ìwádìí ìgbówólórí epo ilẹ̀ àti gáásì ìdáná ní orílẹ̀-èdè láìpẹ́…
“A ko ni nnkankan ti a n fi pamọ o“ -Alakoso NNPC
Àjọ tó ń rí sí epo rọ̀bì lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NNPC) ti fi ìgboyà kéde pé òun kò ní ǹkankan láti fi pamọ́ o,nígbàtí ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lórí ètò ìròyìn ránṣẹ́ pè é.…
Ilé ìfowópamọ́ Àgbáyé Pè Fún Àwọn Àtunṣe Ìgbékalè Láti yọ Àwọn ọmọ Nàìjíríà…
Ẹgbẹ́ ilé ìfowópamọ́ Àgbáyé sọ pé ìgbékalẹ̀ àtúnṣe tí ó jinlẹ̀ ṣe pàtàkì ní kíákíá láti yọ àwọn mílíọ̀nù ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kúrò nínú ìpọ́njú,ó kìlọ̀ pé ìdá mẹ́tàdín-lógún àwọn…