Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN ILẸ̀ ÀFÍRÍKÀ

This is a category for Africa news

Àwọn Aṣòfin Nàìjíríà Yóò Tẹ̀síwájú Nínú Àjọṣepọ̀ Ìdàgbàsókè Pẹ̀lú Orílẹ̀-èdè Kenya

Ilè Ìgbìmọ̀ Aṣojú ṣofin yóò tẹ̀síwájú nínú àjọṣepọ̀ wọ́n pẹ̀lú Kenya lórí ìdàgbàsókè àwọn apá pàtàkì tí ètò-ọrọ àjé. ‎ ‎ Alága, Ẹgbẹ́ Ilé aṣòfin Orílẹ̀-èdè méjèèjì, Ọ̀gbẹ́ni Abdullahi El-rasheed, fúnni ní ìtọ́kasí ní ìpàdé kán pẹ̀lú…

Ìròyìn Ayọ̀: Àrùn Ebola Di Ohun Àfìsẹ́yìn Tí Egúngún Ń Fi Asọ Ní Orílẹ̀-èdè Uganda-…

Ènìyàn mẹ́jọ tí àyẹ̀wò fi hàn pé àrùn Ebola ń yọ lẹ́nu nígbà tí àrùn náà  súyọ ní ọ̀ṣẹ̀ tí ó kọjá ní ó ti wà ní ipò àlàáfíà, tí wọn si ti kúrò ní ilé ìwòsàn   Àjọ WHO gbósùbà fún ìjọba…

Wàhálà Ńlá Bẹ́ Sílẹ̀ Ní Orílẹ̀-èdè Congo, Ọ̀pọ̀ Ènìyàn Sá Àsálà Fún Ẹ̀mí Wọn

Látàrí wàhálà ńlá tí ó ń wáyé ní Orílẹ̀-èdè Congo, àwọn ará ìlú ti ń sá ní kẹ̀tí-kẹ̀tí lọ sí Burundi fún ìdáàbò bò ẹ̀mí wọn   Ní ọ̀ṣẹ̀ tí ó kọjá, ìjọba Orílẹ̀-èdè Burundi fi léde pé àwọn…
button