Nàìjíríà Gbá Àwọn Ọmọ Rẹ̀ Ọgọ́rùn-Àti-Mẹ́jọ Látí Orílẹ̀-èdè Niger
Ìjọba Nàìjíríà tí gbá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè ọgọ́rùn-ún àti mẹ́jọ tí há mọ́ orílẹ̀-èdè Niger ní Pápá kọ òfurufú Murtala Mohamed International, ní Ìlú Èkó, Gúúsù Ìwọ̀-oòrùn Nàìjíríà.
Ipadabọ náà jẹ́ iṣẹ́ Ìjọba Àpapọ̀ ní Ìfọwọ́sowọ́pọ̀…