Browsing Category
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
This is a category for politics news
Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Kí Uzodinma, Ododo Kú Oríire Ìjáwé Olúborí Sí Ipò Gómìnà
Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin, Ọnọrébù Abass Tajudeen ti kí Gómìnà Hope Uzodinma ati Alhaji Ahmed Usman Ododo kú oríire ìjáwé olúborí nínú ìdìbò gómìnà tí ó wáyé ní ọjọ́ Àbámẹ́ta ní ìpínlẹ̀ Imo àti Kogi…
Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Tẹ́lẹ̀rí, Buhari Dáwọ̀ọ́-Ìdùnnú Pẹ̀lú Ẹgbẹ Òsèlú APC…
Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tẹ́lẹ̀rí, Muhammadu Buhari ti kí ẹgbẹ́ òsèlú APC kú oríire fún àseyọrí nínú ìdìbò sí ipò Gómìnà tí ó wáyé ní àwọn ìpínlẹ̀ mẹ́ta ní ọjọ́ Àbámẹ́ta
Ìkíni náà…
Hope Uzodimma Jáwé Olúborí Nínú Ètò Ìdìbò Gómìnà- Soludo kíi Kú Oríire
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Anambra, Ọ̀jọ̀gbọ́n Chukwuma Charles Soludo, CFR, ti kí Sẹ́nétọ̀ Hope Uzodimma ti ìpínlẹ̀ Imo kú oríire fún ìjáwé olúborí rẹ̀ níbi ìdìbò gómìnà èyí tí ó wáyé ní ọjọ́ Àbámẹ́ta, ọjọ́ kọkànlá…
AIG Ṣàpèjúwe Ìdìbò Gómìnà Ìpínlẹ̀ Bayelsa Bí Èyí Tó Ní Àlàáfíà
Ìgbákejì Olórí Ọlọ́pàá tí Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí n ṣé amojuto ìdìbò ní Ìpínlẹ̀ Bayelsa, Gúsù, Nàìjíríà, Ebony Eyiyob, sọ pé ìdìbò Gómìnà ní ìpínlẹ̀ náà jẹ́ èyí tó ní àlàáfíà.
O sọ̀rọ̀ yìí nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú ilé Akéde…
Àwọn Olùgbé Bayelsa Tú Jáde Látí Dìbo
Àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Bayelsa ní Nàìjíríà tí tú jáde láti dìbo lónì látí yàn Gómìnà túntún.
O jú mílíọ̀nù kàn àwọn olùdìbo tá ní ìrètí láti dìbo nínú ìdìbò Gómìnà tó ń wáyé ní ọjọ́ Àbámẹ́ta.
Àwọn gbóògì oludije nínú ìbo Gómìnà náà ní…
Ètò Ìdìbò Ti Ń Lọ Ní Pẹrẹwu Ní Ìpínlẹ̀ Kogi
Ètò ìdìbò ti ń lọ lọ́wọ́ ní ìpínlẹ̀ Kogi níbi ìdìbò sí ipò Gómìnà tí ó ń wáyé ní ìpínlẹ̀ náà
Àwọn ohun èlò ìdìbò àti àwọn òsìṣẹ́ elétò ìdìbò ti wà ní àyè ìdìbò láti òwúrọ̀ kùtù…
Ìdìbò Ìjọba Ìpínlẹ̀ Oṣù kọkànlá: Olórí Ẹgbẹ́ APC Rọ́ Àwọn Olùdìbo Látí Dìbo Fún APC
Òní Ọjọ́ kọkànlá, Oṣù kọkànlá, ọdún 2023 tí ìdìbò yóò wáyé ní ìpínlẹ̀ Imo, Bayelsa àtí Kogi, ìgbákejì alága tí Gúúsù ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Olóyè Emma Eneukwu tí ké sí àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ mẹ́tẹ̀ẹ̀ta láti dìbo fún àwọn Oludije lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́…
Ọkọ Ojú-omí Tó Gbé Àwọn Òṣìṣẹ́ Ìdìbò Àti Àwọn ohun Èlò Ìdìbò Dànù Ní Ìpínlẹ̀ Bayelsa
Àjọ èlèto ìdìbò tí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà INEC, Ìpínlẹ̀ Bayelsa, Gúsù Nàìjíríà, tí fí ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ọkọ̀ Ojú-omí tó ń gbé àwọn òṣìṣẹ́ ìdìbò lọ́ sí ìjọba ìbílẹ̀ Southem Ijaw LGA, ní Ìpínlẹ̀ Bayelsa, àgbègbè Koluama, ló tí dànù.
Adari…
APC kọ ẹsun ti PDP fi kan an lori gomina ipinlẹ Imo
Akọ̀we ìpolongo àpapọ̀ ti ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress, APC, Ọ̀gbẹ́ni Felix Morka ti bẹnu àtẹ́ lu ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party, PDP fún ohun tí wọ́n ṣàpèjúwe rẹ bíi “Àìwúlò pátápátá.”
Ẹgbẹ oṣelu…
Àṣeparí ìdìbò gómìnà : Alága INEC rọ àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìdìbò láti ṣe iṣẹ́ wọn…
Alága ìgbìmọ̀ olómìnira tó ń mójútó ètò ìdìbò lórílẹ̀-èdè, INEC, Ọ̀jọ̀gbọ́n Mahmood Yakubu ri rọ àwọn òṣìṣẹ́ ìgbìmọ̀ náà láti ṣàfihàn bí wọ́n ṣe nífẹ̀ẹ́ orílẹ̀-èdè wọn àti ìmọṣẹ́ wọn bíi iṣẹ́.
O pe…