Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ

This is a category for politics news

Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Tẹ́lẹ̀rí, Buhari Dáwọ̀ọ́-Ìdùnnú Pẹ̀lú Ẹgbẹ Òsèlú APC…

Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tẹ́lẹ̀rí, Muhammadu Buhari ti kí ẹgbẹ́ òsèlú APC kú oríire fún àseyọrí nínú ìdìbò sí ipò Gómìnà tí ó wáyé ní àwọn ìpínlẹ̀ mẹ́ta ní ọjọ́ Àbámẹ́ta Ìkíni náà…

Ìdìbò Ìjọba Ìpínlẹ̀ Oṣù kọkànlá: Olórí Ẹgbẹ́ APC Rọ́ Àwọn Olùdìbo Látí Dìbo Fún APC

Òní Ọjọ́ kọkànlá, Oṣù kọkànlá, ọdún 2023 tí ìdìbò yóò wáyé ní ìpínlẹ̀ Imo, Bayelsa àtí Kogi, ìgbákejì alága tí Gúúsù ẹgbẹ́ òṣèlú APC, Olóyè Emma Eneukwu tí ké sí àwọn olùgbé ìpínlẹ̀ mẹ́tẹ̀ẹ̀ta láti dìbo fún àwọn Oludije lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́…

Ọkọ Ojú-omí Tó Gbé Àwọn Òṣìṣẹ́ Ìdìbò Àti Àwọn ohun Èlò Ìdìbò Dànù Ní Ìpínlẹ̀ Bayelsa

Àjọ èlèto ìdìbò tí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà INEC, Ìpínlẹ̀ Bayelsa, Gúsù Nàìjíríà, tí fí ìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé ọkọ̀ Ojú-omí tó ń gbé àwọn òṣìṣẹ́ ìdìbò lọ́ sí ìjọba ìbílẹ̀ Southem Ijaw LGA, ní Ìpínlẹ̀ Bayelsa, àgbègbè Koluama, ló tí dànù. Adari…

Àṣeparí ìdìbò gómìnà : Alága INEC rọ àwọn òṣìṣẹ́ elétò ìdìbò láti ṣe iṣẹ́ wọn…

Alága ìgbìmọ̀ olómìnira tó ń mójútó ètò ìdìbò lórílẹ̀-èdè, INEC, Ọ̀jọ̀gbọ́n Mahmood Yakubu ri rọ àwọn òṣìṣẹ́ ìgbìmọ̀ náà láti ṣàfihàn bí wọ́n ṣe nífẹ̀ẹ́ orílẹ̀-èdè wọn àti ìmọṣẹ́ wọn bíi iṣẹ́. O pe…
button