Browsing Category
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
This is a category for politics news
Adari ilé ìgbìmọ̀ Abbas Ki Wike Ku Órire Ayẹyẹ Ọjọ Ibi Re Ni Ẹni Mẹ́rìndínlọ́gọ́ta.
Adari ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Abbas Tajudeen ti ba ọlọ́jọ́ìbí Nyesom Wike yajo ọjọ́ ìbí re ni ẹni Mẹ́rìndínlọ́ọ̀gọ́ta loke ìpẹ̀.
Abbas ṣe àpèjúwe rẹ gẹ́gẹ́ bí ẹni tí o ṣe fi okan tan nipa iṣẹ rẹ sí Orílẹ̀-èdè Nàìjíría.
Olubadamoran pataki…
Ètò Ìsúná Ọdún 2024: Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Pe Ìpàdé Àpérò Pẹ̀lú Ará Ìlú
Lójúnà àti jẹ́ kí ìjọba tiwa-n-tiwa fi ìdí múlẹ̀ sinsin, Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin, Ọnọrébù Abbas Tajudeen pe ìpàdé àpérò pẹ̀lú ará ìlú lórí ètò ìsúná ọdún 2024 èyí tí ó wáyé ní ìlú Abuja
…
Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ìpínlẹ̀ Benue Pàṣẹ Títúléká Ní Àwọn Ìjọba Ìbílẹ̀- Agbẹnusọ…
Ìjọba ìpínlẹ̀ Benue ti sàlàyé pé títú àwọn ìjọba ìbílẹ̀ ká tí ó wáyé ní ìpínlẹ̀ Benue wà ní ìbámu pẹ̀lú òfin, lẹ́yìn àgbéyẹ̀wò tí ó wáyé láti ọwọ́ àwọn ọmọ Asofin Ìpínlẹ̀ náà
Sir Tersoo Kula,…
Adari ilé ìgbìmọ̀ Nasarawa tuntun pinnu ìṣàkóso tí yóò kó gbogbo ènìyàn mọ́ra
Adari ilé ìgbìmọ̀ tuntun ti ìpínlẹ̀ Nasarawa Hon. Danladi Jatau Angbo ti pinnu láti ṣe ìṣàkóso tí yóò kó gbogbo ènìyàn mọ́ra ni ìpínlẹ̀ naa.
Jatau sọ eleyi di mimọ nigba ti awọn olugbe ijọba ibilẹ Kokona ti ipinlẹ…
APC Anambra gba Sẹ́nétọ̀ Ubah, Ekwunife wọlé sínú ẹgbẹ́
Ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC), ikọ̀ ìpínlẹ̀ Anambra ti gba Sẹ́nétọ̀ tí ń ṣojú Gúsù ìjọba Agbègbè Anambra, Sẹ́nétọ̀ Ifeanyi Ubah àti Sẹ́nétọ̀ tí ó sojú Àringbùngbùn agbègbè ìjọba àpapọ̀ tẹ́lẹ̀ rí tí…
INEC bẹnu àtẹ́ lu ìgbógunti olú ilé iṣẹ́ ní Kogi
Ìgbìmọ̀ Olómìnira tí ń mójútó ètò ìdìbò lórílẹ̀-èdè, INEC, ní ìpínlẹ̀ Kogi , Àringbùngbùn Nàìjíríà ti bẹnu àtẹ́ lu bí àwọn ènìyàn kan ṣe ya lu olú ilé iṣẹ́ rẹ̀ ní Lokoja, olú ìlú, tí wọ́n sì dí…
Ẹ Máa Jó Jàgínní Yòdò: Àlékún Ti Débá Àkókò Ìfẹ̀yìntì Fún Àwọn Òsìṣẹ́ Ìjọba…
Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ìpínlẹ̀ Kogi ti se òfin èyí tí ó se àgbéyẹ̀wò àkókò ìfẹ̀yìntì, tí ó sì mú àlékún bá àkókò náà láti ọgọ́ta ọdún tí ó sì di ọdún márùnlé-lọ́gọ́ta
Àwọn asòfin gbé…
Ile ́Ẹjọ́ Yọ Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ìpínlẹ̀ Nasarawa, Ó kéde Olùdíje Lábẹ́ Ẹgbẹ́…
Ilé Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn tí ó wà ní ìlú Abuja ti yọ adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ìpínlẹ̀ Nasarawa, Ọnọrébù Ibrahim Balarabe Abdullahi tí ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ òsèlú APC nípò.
Wọ́n yọ adarí ilé náà nípò…
Ilé Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn Fi Ìdí Ìjáwé Olúborí Kefas Múlẹ̀ Gẹ́gẹ́ Bí Gómìnà Tí Wọ́n…
Ilé Ẹjọ́ Kòtẹ́milọ́rùn tí ó wà ní ìlú Abuja ti fi ìdí ìjáwé olúborí Ọ̀mọ̀wé Kefas Agbu ti ẹgbẹ́ òsèlú PDP múlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹni tí ó jáwé olúborí nínú ìdìbo gómìnà tí ó wáyé ní ọjọ́ kejìdínlógún…
Gómìnà ìpínlẹ̀ Nasarawa Dẹ̀kun Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP Láti Ta Àbùkù Bá Orúkọ Àwọn Adájọ Ni Ìpínlẹ̀ Náà.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Nasarawa ti dẹ́kun ẹgbẹ́ òṣèlú PDP láti má ṣe bú enu àbùkù Lu orúkọ àwọn adájọ ìpínlẹ̀ náà nitori eto ìdìbò to wáyé.
Nínú ọ̀rọ̀ àtẹ̀jáde kàn tí Akọ̀wé àgbà fún Gómìnà ìpínlẹ̀ náà Abdullahi Sule sọ, Akọ̀wé fún ọ̀rọ̀ gbogbo,…