Browsing Category
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
This is a category for politics news
Kò Sí Aburú Nínú Ká Máa Polongo Ìbò De Ọdún 2027- Sénétọ̀ Ashiru
Igbákejì Olórí àwọn Sénétọ̀ ninu ile igbimọ aṣòfin, Senator Lola Ashiru
ti sọ pe òun ko ri ohun to burú nínú pé olóṣèlú ki olóṣèlú máa polongo ìbò sílẹ fún ọdún 2027 láti ìsisìyí lọ.
Botilejepe òun kò leè lọwọ nínú…
Ẹgbẹ́ Òsèlú APC Yóò Jáwé Olúborí Nínú Àtúndì Ìbò Ní Ìpínlẹ̀ Jigawa
Ẹgbẹ́ òsèlú APC ti fi ìfọ̀kànbalẹ̀ sọ̀rọ̀ wípe ẹgbẹ́ òsèlú náà yóò jáwé olúborí nínú àtúndì ìbò ilé ìgbìmọ̀ asòfin Abuja tí ẹkùn Brinin Kudu/ Buji, ìpínlẹ̀ Gigawa
Alága ẹgbẹ́ ní ìpínlẹ̀…
Àjọ INEC Ìpínlẹ̀ Gombe Kéde Ọjọ́ Kẹtàdínlọ́gbọ̀n Osù Kẹrin Fún Ìdìbò Ìjọba Ìbílẹ̀
Àjọ Elétò Ìdìbò ti kéde ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n osù kẹrin ọdún 2024 gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ tí gómìnà ìpínlẹ̀ Gombe, Muhammadu Inuwa Yahaya fi ọwọ́ sí, fún síse ètò ìdìbò ìjọba ìbílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ náà
Nígbà tí…
Mímú Ìdàgbàsókè Bá Ìlànà Ètò Òsèlú Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Se Pàtàkì-…
Gómìnà Umo Eno ti Ìpínlẹ̀ Akwa Ibom ti pàrọwà sí àjọ elétò ìdìbò láti mú ìdàgbàsókè bá ètò ìdìbò Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà fún ìfìdí múlẹ̀ ìjọba tiwa-n-tiwa
Eno sọ ọ̀rọ̀ náà nígbà tí…
Ilé Ẹjọ́ Gíga Da Ìrawọ́ Ẹ̀bẹ̀ Tí Ẹgbẹ́ Òsèlú ADC Se Láti Tako Ìjáwé Olúborí Gómìnà…
Ilé Ẹjọ́ gíga ti da ìrawọ́ ẹ̀bẹ̀ ti olùdíje sí ipò gómìnà lábẹ́ ẹgbẹ́ òsèlú ADC, Nafiu Bala se láti tako ìjáwé olúborí gómìnà Muhammad yahaya ti ìpínlẹ̀ Gombe
Àwọn adájọ márùn-ún tí Adájọ́ Kudirat…
Látàrí Ìdájọ́ Ilé Ẹjọ́ Gíga Lórí Awuye-wuye Tí Ó Wáyé Níbi Ìdíje Sí Ipò Gómìnà…
Kò dín ní ẹgbẹ̀rún ènìyàn tí ó jẹ́ alátìlẹyìn Kwankwasiyya ni ó péjọ ní ìjọba ìbílẹ̀ Keana, Ìpínlẹ̀ Nasarawa láti se àjọyọ̀ ìdájọ́ ilé ẹjọ́ àpapọ̀ èyi ́tí ó fi ìdí ìjáwé olúborí Abba kabir Yusuf múlẹ̀…
Adarí ilé ìgbìmọ Plateau fi àtìlẹyìn ilé aṣòfin dá gómìnà Mutfwang lójú
Adarí, ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Plateau , Gabriel Dewan, ti fi àtìlẹyìn ilé aṣòfin dá gómìnà Caleb Mutfwang lójú láti jẹ́ kí ó ṣe àṣeyọrí. Dewan ṣe idaniloju yi ni ọjọ Abamẹta, nibi igbalejo lati yẹ Mutfwang si lẹyin aṣeyege…
Gombe: NSCDC ké gbàjarì lórí àkóràn ààrùn tí kò gbóògùn láàrin àwọn obìnrin
Adarí ẹgbẹ́ tí ń mójútó ààbò Nàìjíríà àti ìdáàbòbò ará ìlú (NSCDC), ti ìpínlẹ̀ Gombe ti ké gbàjarì, pé àwọn ọmọ bìnrin kan tí wọ́n ti kó ààrùn kògbóògùn HIV/AIDS ti ya wọ ìpínlẹ̀ Gombe, olú ìlú…
Ilé Ejọ́ Gíga Jùlọ Da Ẹjọ́ Tí Ẹgbẹ́ Òṣèlú SDP Pè Nù
Ilé Ejọ́ gíga jùlọ ni orilẹ-ede yii ti da ẹjo kòtẹ́milọ́rùn ti Ẹgbẹ́ Oselu SDP àti Oludije gomina re, Dókítà Umar Ardo pé lati takò ìjàwé olubori Ahmadu Fintiri gege bi gomina ipinle Adamawa nu.
Ìwé ìpèjọ́, SC/CV/1219/2023 náà…
Alága APC ṣàjọyọ̀ pẹ̀lú gómìnà Alia lórí àṣeyọrí ilé ẹjọ́ gíga
Alága ẹgbẹ́ òṣèlú tí ń ṣèjọba All Progressives Congress (APC), Dókítà Abdullahi Umar Ganduje ti kí gómìnà Hyacinth Alia ti ìpínlẹ̀ Benue lórí àṣeyọrí ilé ẹjọ́ gíga.
Ganduje ninu alaye kan lati ọdọ Akọwe agba rẹ fun…