Browsing Category
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
This is a category for politics news
PDP yan Toyese ní igbákejì alága iwọ̀ oòrùn lápapọ̀
Ìgbìmọ̀ ìsiṣẹ́ lápapọ̀, NWC ti ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party, PDP ti gbìmọ̀ pọ̀ yan Ọ̀gbẹ́ni Ajisafe Toyese láti ìpínlẹ̀ Ọṣun ní igbákejì alága iwọ̀ oòrùn lápapọ̀ fún ẹgbẹ́ náà.
Eleyii wa ninu alaye kan ti…
Àwọn Gómìnà Lábẹ́ Ẹgbẹ́ Òsèlú PDP Sàgbékalẹ̀ Ọ̀bítí-bitì Owó Fún Àwọn Tí Ó Fi Ara…
Àwọn Gómìnà tí wọ́n Yànsípò Lábẹ́ ẹgbẹ́ òsèlú PDP ti fi Ọgọ́rùn-ún Mílíọ̀nù náírà sé ìtọrẹ àánú fún àwọn tí ó fi ara káásá níbi ìkọlù tí ó wáyé ní Bokkos, Mangu, ní ìjọba ìbílẹ Barkin, ìpínlẹ̀…
Àdíkù Yóò Dé Bá Ìgbòkè-gbodò Ní Ìpínlẹ̀ Kano Látàrí Àtúndì Ìbò Tí Yóò…
Àjọ Ọlọ́pàá Ìpínlẹ̀ Kano ti sàlàyé pé àdíkù yóò bá lílọ-bíbọ̀ ní ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fẹ́ẹ̀fà níbi tí ìrètí wà pé àtúndì ìbo yóò wáyé ní ìpínlẹ̀ náà
Kọmísọ́nà àjọ Ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Kano,…
Àtúndì Ìbò Ìpínlẹ̀ Ebonyi – Mílíọ̀nù Mẹ́ta Ènìyàn Darapọ̀ Mọ́ Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC
Àtúndì Ìbò Ìpínlẹ̀ Ebonyi - Mílíọ̀nù Mẹ́ta Ènìyàn Darapọ̀ Mọ́ Ẹgbẹ́ Òṣèlú APC
Gomina ipinle Ebonyi, ọgbẹni Mr Francis Nwifuru ti fi ìdùnnú rẹ hàn latari bi awọn eniyan se tu jade ni yanturu lati ṣe atilẹyin fún ipolongo ibo fún ọmọ ẹgbẹ…
Máa Jó Lọ A Wà Lẹ́yìn Rẹ Bi Iké – Ìgbìmọ̀ Ẹgbẹ́ PDP Ìpínlẹ̀ Kogi
Ìgbìmò Kọmití ẹ̀ka Ẹgbẹ́ PDP ìjọba ibile Dekinat, ìpínlẹ̀ Kogi ti sọ pe alaga ijoba ibile, Alhaji Hussain Ibrahim wẹ̀, ó tún yán kàìnkàìn.
Kọmiti náà ninu akosile ti wọ́n gbe jade ni ilu Lokoja ni ọjọ Aje yẹra fún ọrọ kan to já…
Àjọ INEC Yóò Pèsè Ẹgbẹ̀rún Mẹ́rin Òsìṣẹ́ Fún Àtúndì Ìbò Tí Yóò Wáyé Ní Ìpínlẹ̀…
Àjọ INEC ti fi ìgbáradì rẹ̀ hàn láti pèsè ẹgbẹ̀rún mẹ́rin òsìṣẹ́ fún àtúndì ìbò tí yóò wáyé ní ọjọ́ Àbámẹ́ta, ọjọ́ kẹta osù kíní ọdún 2024, ní ìpínlẹ̀ kaduna
Alákòóso àjọ náà fún ìpínlẹ̀…
Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Láti Tán Ìsòro Àìrajaja Ààbò Ní Àgbègbè Abuja Se Kókó- Ọmọ Ilé…
Ọmọ Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin tí ó ń sojú ẹkùn Anac/Bwari ní ìlú Abuja, Josua Chinedu Obika ti ké sí àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ láti fọwọ́sowọ́pọ̀ lójúnà àti wá ojútùú sí ìsòro àìrajaja ààbò ní olú ìlú Orílẹ̀-èdè…
A Ti Gbaradì Láti Bèrè Iṣé : Gómìnà Tuntun Ti Won Yan.
Gbogbo ẹtọ ti to báyìí fún Ìfini sí Ipò Gómìnà ni ìpínlẹ̀ Kogi .
Àgọ mẹsan òwúrọ̀ ni ayeye náà yóò bẹ̀rẹ̀ níbè Gómìnà Yahayah Bello yóò gbe ìjọba fún Gómìnà tuntun ti wọn yan fún ìpínlẹ̀ náà láti bẹrẹ iṣẹ ni perewú.
Awọn eleto ààbò…
Àwọn ọba Anambra fi àtìlẹyìn wọn dá gómìnà Soludo lójú
Alága, ìgbìmọ̀ àwọn lọ́balọ́ba ti ìpínlẹ̀ Anambra, Obi ti Onitsha, Igwe Alfred Achebe, ti túnbọ̀ fi àtìlẹyìn wọn dá gómìnà ipinlẹ naa Ọjọgbọn Chukwuma Soludo lójú.
Achebe, ninu ipade kan laarin gomina ipinlẹ naa ati awọn…
Lórí Àtúndì Ìbò Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Àpapọ̀ Ní Ìpínlẹ̀ Ebonyi, Ìdí Tí Mo Fi…
Olùdúje sí ilé ìgbìmọ̀ Asòfin àpapọ̀ lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ òsèlú APC ní Ìpínlẹ̀ Ebonyi, Arábìnrin Ann Agom-Eze ti fi ìdí pàtàkì hàn látàrí ìgbésẹ̀ rẹ̀ bí ó se kùnà láti fi ìwé ìkópa èyí tí ó rà sọwọ́…