Browsing Category
Ó GBÓNÁ FẸLI-FẸLI
This is a category for LATEST NEWS
Ààrẹ Tinubu kí Jim Ovia kú oríire ṣíṣàtẹ́wọ́gbà rẹ̀ sí Ìjọlá ìlú London
Ààrẹ Bọla Tinubu ti kí Jim Ovia, olùdásílẹ̀ tí ó tún jẹ́ Alága ilé ìfowópamọ́ Zenith, kú oríire ṣíṣàtẹ́wọ́gbà rẹ̀ sí Ìjọlá ìlú London.
Ninu Atẹjade kan lati ọdọ agbẹnusọ Aarẹ, Ọgbẹni Bayo Onanuga, Aarẹ…
Ẹgbẹ́ ọmọ ilé àwọn tí kò pọ̀ bẹnu àtẹ́ lu Ìpànìyàn tó wáyé ní Ìpínlẹ̀ Edo
Ẹgbẹ́ ọmọ ilé Aṣojú ti àwọn tí kò pọ̀, ti bẹnu àtẹ́ lu bí ẹgbẹ́ oníjàgídíjàgan kan ní ìpínlẹ̀ Ẹdo ṣe ṣekú pa àwọn ọmọ Nàìjíríà tí kò dín ní mẹ́rìndín-lógún, tí àwọn ọmọ bíbí inú Arewa pọ̀jù lọ nínú wọn,…
Igbákejì Ààrẹ Shettima rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti gbé pọ̀ pẹ̀lú Ìṣọ̀kan àti…
Igbákejì Ààrẹ Kashim Shettima ti rọ àwọn ọmọ Nàìjíríà láti gbé pọ̀ pẹ̀lú Ìṣọ̀kan Àlàáfíà àti ìfaradà gẹ́gẹ́ bíi òpo pàtàkii ìdàgbàsókè orílẹ̀-èdè, bí ẹ̀kọ́ tí ó wà nínú Ramadan.
O sọrọ ni…
Ààrẹ Tinubu Gba Olórí Orílẹ̀-èdè Ghana Lálejò
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti gba adarí orílẹ̀-èdè Ghana, John Mahama lálejò ní ìbùgbé ààrẹ, Abuja tii ṣe Olu ìlú Nàìjíríà.
Ààrẹ Mahama balẹ̀ gùdẹ̀ sí ìbùgbé ààrẹ ní déédé aago Méjì ààbọ̀ ọ̀sán ọjọ́ Ọjọ́bọ̀. Àkọ́kọ́ àbẹ̀wò rẹ̀…
Ológun Gbàjọba Olú Ilé Ise Ilé Ìfowópamọ́ Àgbà Orílẹ̀-èdè Sudan
Àwọn ọmọ ológun ilẹ̀ Sudan ti gbàsàkóso olu ilé iṣẹ Ilẹ́ Ìfowópamọ́ àgbà Orílẹ̀-èdè Sudan, ologun meji sọ èyí fún oníròyìn ni ọjọ́ Àbámẹ́ta, eyi tii ṣe igbese nla míràn pataki ìtèsíwájú ogún lòdì si àwọn ikọ̀
paramilitary Rapid…
Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Yóò Se Ìjíròrò Lórí Ìkéde Ìjọba Pàjáwìrì Tí Ó Wáyé Ní…
Àrídájú ti wà pé Ilé Asòfin Àgbà Yóò Se ìjíròrò ní Ọjọ́bọ̀ lórí ìkéde ìjọba pàjáwìrì tí ó wáyé ní ìpínlẹ̀ Rivers, Sẹ́nétọ̀ Jimoh Ibrahim ni ó fí ọ̀rọ̀ náà léde
Alága ìgbìmọ̀ tí ó ń rí…
Quadri Aruna Ló Dára Jù Nílẹ̀ Adúláwọ̀ Nínú Eré Bọ́ọ̀lù Ẹlẹ́yin Orí Tábìlì
Quadri Aruna ti jẹ́ agbábọ́ọ̀lù ẹlẹ́yin lórí tábìlì tó dára jùlọ ní ilẹ̀ Adúláwọ̀ báyìí, ó sún sí ipò kejìdínlógún lágbáyé.
Ó ti síwájú ọmọ orílẹ̀-èdè Egípítì, Omar Assar láti jẹ́ ẹni tó dara jùlọ nínú bọ́ọ̀lù gbígbá ẹlẹ́yin lórí tábìlì tó…
DR Congo, Rwanda Pè Fún Ìdáwọ́ Ogun Dúró
Ààrẹ orílẹ̀-èdè olómìnira Congo, Félix Tshisekedi àti ti orílẹ̀-èdè Rwanda, Paul Kagame ti pè ipe ìdáwọ́ogun dúró ní ìlà oòrùn DR Congo ní kíámọ́sá lẹ́yìn ìpàdé wọn tó wáyé ní Qatar.
Ó jẹ ìgbà àkọkọ ti àwọn olórí méjèèjì náà yòo se ìpàdé…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Nasarawa Ṣèlérí Àkànṣe Isẹ́ Amúlúdàgbà Láì Yáwó Kiri
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Nasarawa ti sèlérí àkànṣe iṣẹ amúlúdàgbà lai yáwó kiri ilé ifowopamọ fún ìpínlẹ̀ Nasarawa.
Ó sọ eyi nibi ìtunu ààwẹ̀ Ramadan níbi tó ti gbá àwọn olóyè Egbe oniroyin lalejo-omo Egbe ajo Nigerian Union of Journalists (NUJ),…
Ààrẹ Tinubu Kí Osuide Kú Oríire Ní Ẹni Àádọ̀rún Ọdún
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti kí Ọ̀jọ̀gbọ́n Gabriel Osuide, Ọ̀mọ̀wé, apoògùn àti èèkàn elétò ilera bí o ti ń se ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọmọ Àádọ̀rún ọdún.
Ààrẹ Tinubu darapọ̀ mọ́ ìdílé Kòfésọ̀ Osuide, ará àti ọrẹ elétò ilera Nàìjíríà ẹbí Ọ̀mọ̀wé nípa…