Browsing Category
Ó GBÓNÁ FẸLI-FẸLI
This is a category for LATEST NEWS
Ètò Ìfilọ́lẹ̀ Láti Jẹ́ Olórí Kátólìkì Túntún Bẹ̀rẹ̀
Ayé n dúró dè àbájáde ìfilọ́lẹ̀ Olórí Kátólìkì Túntún, tó bẹ̀rẹ ní ọjọ́ kéje Oṣù Kàrún ọdún 2025, bí àwọn kadinali ṣé pejọ ní 'Vatican' láti yán olórí tí Kátólìkì.
Ikú Pope Francis ní ọjọ́ kọkanlelogun, Oṣù Kẹ́rin, ọdún 2025, ní ẹni…
Ìgbìmọ̀ Aláṣe Àpapọ̀ FEC buwọ́lu ìwé òfin tí yóò dá ìgbìmọ̀ tí ń rísí Ìṣàkóso…
Ìgbìmọ̀ Aláṣe Àpapọ̀ (FEC), tí Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu jẹ́ alága rẹ̀ ti buwọ́lu ìwé òfin tí yóò dá ìgbìmọ̀ tí ń rísí Ìṣàkóso Kòkóó (NCMB), sílẹ̀ tí èyí sì jẹ́ ìgbésẹ̀ pàtàkì láti ṣàgbéǹde ilé iṣẹ́…
Àjọ NUPEC Gbáradì Láti Dá Ààbò Bo Àwọn Ibi Ìwakùsà
Àjọ National Unity and Peace Corps, NUPEC sọ pé àwọn ti ṣetán ju àtẹ̀yìn wá lọ láti fi ààbò bo àwọn ibi Ìwakùsà káàkiri orílẹ̀-èdè yìí látàrí ìwé àbádòfin Ìfilọ́lẹ̀ tó de àjọ náà ti wọ́n yóò buwọ́lù.
Ọ̀gá àgbà patapata àjọ náà,…
Aṣọ Ológun Tí Àwọn Ènìyàn Kan Ńwọ̀ Lòdì Sí Ètò Ààbò – Ológun Ṣe Ìkìlọ̀
Awọn ọmọ ológun orílè-èdè Nàìjíríà tí rọ àwọn olùgbé orílẹ̀-èdè yìí láti yàgò fún wíwọ aṣọ ológun wọn láì se ọmọ ológun Nàìjíríà nitori ṣíṣe èyí a máà tàbùkù bá ìyí àwọn ọmọ Ológun, a sì máa mú kí ètò ààbò bẹ́ rẹ́lẹ̀.
Nígbàtí ó ń…
CAF Kéde Àwọn igbákejì Ààrẹ tuntun níbi ìpàdé ìgbìmọ̀ Aláṣẹ
Ìgbìmọ̀ Aláṣẹ (EXCO) fún Ìgbìmọ̀ Ẹgbẹ́ Agbábọ́ọ́lù Láfíríkà (CAF) ti ṣe ìpàdé ní Accra, Ghana, ní ọjọ́ Àbámẹ́ta ṣíwájú ìfigagbága eré bọ́ọ́lù àṣekágbá àwọn ilé ẹ̀kọ́ Agbábọ́ọ́lù Láfíríkà CAF.
Aarẹ…
Igbákejì Adarí ilé pè fún àtìlẹyìn Gúsù ilà oòrùn fún àtúnyàn Ààrẹ Tinubu
Igbákejì Adarí ilé ìgbìmọ̀ Aṣojú, Ọ̀gbẹ́ni Benjamin Kalu, ti sọ pé sáà kejì tọ́ sí Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu tí a bá wo àwọn àṣeyọrí tí ó ti ṣe lórí àtúnṣe pàtàkì lórí ọrọ̀ ajé, àjọṣepọ̀ ará ìlú àti…
Mínísítà ṣe ìfilọ́lẹ̀ ilé iṣẹ́ irin Irínwó Mílíọ́nù Dọ́là ní ìpínlẹ̀ Ogun
Mínísítà Nàìjiríà fún ìdàgbàsókè Irin, Ọmọ Ọba Shuaibu Abubakar Audu, ti ṣe àjọyọ̀ ìfilọ́lẹ̀ gbangba ti ilé iṣẹ́ irin Inner Galaxy Group’s Stellar, idokowo Irínwó Mílíọ́nù Dọ́là ní ìpínlẹ̀ Ogun ní Gúsù Iwọ̀…
Abia 2027: Àwọn Adarí agbègbè rọ igbákejì adarí ilé láti díje Gómìnà
Àwọn agbaagba Ukwa-Ngwa ní gbègbè Aba ìgbà kan rí ní ìpínlẹ̀ Abia Abia ti bẹ igbákejì adarí ilé ìgbìmọ̀ Aṣòfin, Ọlọla Benjamin Okezie Kalu, láti díje fún ipò Gómínà nínú ìbò gbogbogbòò ọdún 2027.
Awọn…
Ààrẹ Tinubu kí adarí Itsekiri kú àádọ́ta ọdún
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti kí Ayirimi Emami, ẹni tí ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn adarí Itsekiri, oníṣòwò, àti olùṣàánú, fún àjọyọ̀ àádọ́ta ọdún rẹ̀.
Ninu alaye kan lati ile iṣẹ Aarẹ, Aarẹ gboriyin fun Emami fun awọn ipa…
Adarí orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Tinubu padà wálé ní ọjọ́ Ajé
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu yóò padà sí Nàìjíríà ní ọjọ́ Ajé, ọjọ́ kọkàlé-lógún, oṣù kẹrin lẹ́yìn àbẹ̀wò iṣẹ́ sí Yúróópù.
Agbẹnusọ Aarẹ, Bayo Onanuga, ni o kede rẹ wẹrẹ lori ayelujara X, bayii pe “Aarẹ Bola Tinubu…