Browsing Category
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
This is a Nigeria news category
Ààrẹ Tinubu Ṣàfihàn Ìlọsíwájú Ẹgbẹ́ APC Sí Àwọn Àtúnṣe Ètò Ọrọ-àjé
Ààrẹ Bola Tinubu tí sọ pé àtìlẹ́yìn tó ń pọ̀ sí i fún ẹgbẹ́ òṣèlú 'All Progressives Congress' (APC) ló jẹ́ àṣeyọrí àgbàyanu tí ẹgbẹ́ náà ṣe láàárín ọdún méjì àkọ́kọ́ tí wọ́n ti lò lẹ́nu iṣẹ́ ìjọba, ó sì fi dá àwọn ọmọ Nàìjíríà lójú pé…
Ètò Ẹ̀kọ́: Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Rẹmi Tinubu Bèrè Anfààní Ẹ̀kọ́ Ọfẹ Fún Àwọn Ọ̀dọ́.
Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Oluremi Tinubu, sọ wí pé oun ṣiṣe lórí bí ètò ẹ̀kọ́ ọfẹ yóò ṣẹ wa fun àwọn ọ̀dọ́
Nígbà tí o ń ba aláṣẹ ilé iṣé MERCK Foundation sọ̀rọ̀, ilé iṣé ti o jẹ aláàdáni láti Orílẹ̀-èdè German nígbà tí wọn ṣe àbẹ̀wò…
Ọ̀jọ̀gbọ́n Soyinka Polongo Gbígbé Èdè Àbínibí Ilẹ̀ Wa Lárugẹ
Ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka-"Nobel Laureate", ti tẹnumọ bó ṣe se pàtàkì láti gbé èdè abínibí ilẹ̀ wá àti àṣà òjogúnbá lárugẹ, wípé ó jẹ́ ohun ìwúlò pàtàkì fún ìdàgbàsókè orílẹ̀-èdè .
Ó sọ èyí ní ọjọ́ Ajé níbi ti o ti ń dáhùn ìbéèrè láti ọdọ…
Ipinlẹ Anambra Gbé Ìgbésẹ Akínkanjú Nípa Títún Àyíká Àti Bèbè Omi Ṣe.
Ìjọba ìpínlẹ̀ Anambra pẹ̀lú àjọsọpọ̀ - "Initiative for Agulu Development" ní ọnà láti ṣe ìmọ́tótó sì àwọn agbègbè ti omi wà àti àwọn àyíká rẹ àti ni ọ̀nà láti jẹ́ kí ẹ̀gbin omi dínkù, wọn ti ṣètò ìmọ́tótó ní gbogbo bèbè omi àti…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kwara Ri Asia Iṣọkan
Àárín gbùngbùn ipinlẹ Kwara ti ri ásíà iṣọkan oní àádọ̀rin Mítà ní gíga ti gómìnà AbdulRahman AbdulRazaq pé ìtúmọ̀ rẹ̀ ní "Iṣọkan àpapọ̀" - “national unity", àjọsọpọ Irinajo wà àti èròngbà wà gẹ́gẹ́ bí ènìyàn.
Ní ibi…
Àjọ NELFUND Bẹ̀rẹ̀ Pinpin Owó Àlàkalẹ̀ Ti Oṣù Kẹrin
Àjọ Nigerian Education Loan Fund (NELFUND) ti bẹ̀rẹ̀ pinpin Owó ẹ̀yá àlàkalẹ̀ ti Oṣù Kẹrin ọdún 2025 fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ tó peregede fún un jákèjádò Nàìjíríà.
Àkọsílẹ̀ láti ọdọ Alakoso àjọ Strategic Communications owó náà, Ìyáàfin Oseyemi…
Mínísítà Ọ̀rọ̀ Nípa Àwọn Obìnrin Kí Ọpẹ́yẹmí Bright Kú Oríire Oyè Mayor.
Mínísítà tó ń ri sì ọ̀rọ̀ nípa àwọn Obìnrin, Hajiya Imaan Sulaiman-Ibrahim ti kí Princess Opeyemi Bright ku oríire bí o ti fìtàn balẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọ̀dọ́mọdebìnrin tó kéré jùlọ Mayor ní ilẹ̀ Gẹ̀ẹ́sì.
Bí ètò ifinijoye rẹ yóò ṣe…
Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP Ní Ìlà Oòrùn Gúsù Ti Kìlọ Látàrí Ìpè Ìpàdé Àwọn Alẹ́nulọ́rọ̀ Tó Jẹ́ Òfegè
Ẹgbẹ́ Òṣèlú PDP Ní Ìlà Oòrùn Gúsù ti kìlọ fún àwọn ọmọ ẹgbẹ́ rẹ̀ láti má ka ìpè ipàdé pàjáwìrì àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ ní Abuja sí.
Nínú àkọsílẹ̀ ìròyìn kan, alukoro ẹgbẹ́ ní ẹ̀ka ìlà oòrùn gusu, Chigozie Igwe, tẹnumọ…
Burna Boy Yóò Se Eré Ọ̀fẹ́ Fún Àwọn Ololufẹ Rẹ̀ Ní Orílè-èdè Burkina Faso
Ìràwọ akọrin ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà sọ èyí di mímọ̀ lórí ẹ̀rọ ayélujára Instagramu rẹ̀ ni ọjọ́ kẹtàdínlogun oṣù kàrún ọdún 2025 pé òun ṣe eré ní orílẹ̀-èdè Burkina Faso.
"Ti o bá seése, fún mi, iyì ni yóò jẹ fún mi láti seré ọ̀fẹ́…
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kéde Ìbẹ̀rẹ̀ Àjọ̀dún Eré Ìdárayá Orílẹ̀-èdè
Tí ìdùnnú tí ayọ̀ ní gbogbo àwọn ènìyàn wà nílùú Abeokuta, tó jẹ́ olu-ilu ìpínlẹ̀ Ogun, nígbà tí Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ṣe kéde ayẹyẹ eré ìdárayá ẹlẹ́ẹ̀kejìlélógún ní ìforígbárí, pẹ̀lú àwọn olóyè, àwọn olóṣèlú, àwọn ògbóǹtagí eré ìdárayá…