Browsing Category
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
This is a Nigeria news category
FIFA Ṣàfihàn Orúkọ Àwọn Ọmọ Nàìjíríà Tí Yóò Jẹ́ Olùdarí Eré Ìdárayá ti 2026
FIFA ti ṣe àkójọpọ̀ Orúkọ Àwọn Ọmọ Nàìjíríà tí yóò jẹ́ Olùdarí eré ìdárayá ní Àgbáyé ti ọdún 2026 ní gbángba, ó sì jẹ́rìí sí i pé àwọn ọgbọ̀n (30) ní a fọwọ́ sí láti dárí àwọn ìdíje àgbáyé ní onírúurú ẹ̀ka.
Àkójọpọ̀ ọdọọdún náà ní…
Àwọn Ọgá Àgbà VON, FRCN Gbóríyìn Fún Zulum Bí Borno Ṣé Ṣàfihàn Àṣà
Àtúnṣe ìrìn-àjò ìgbáfẹ́ ní Ìpínlẹ̀ Borno gba ìdàgbàsókè ńlá bí Olùdarí Àgbà fún Ilé Akéde Nàìjíríà "Voice of Nigeria (VON)", Malam Jibrin Baba Ndace, àti Olùdarí Àgbà fún Ilé-iṣẹ́ Radio Ìjọba "Federal Radio Corporation of Nigeria (FRCN)",…
Gómìnà Aiyedatiwa Ṣàlékún ààbò jákè jádò Ìpínlẹ̀ Ondo
Gómìnà ìpínlè Ondo, Lucky Aiyedatiwa, ti pàse fún àwon elétò ààbò láti túnbọ̀ lékún ìpààrà lórí ààbò jákè kádò àwọn agbègbè àti agbègbè aginjù látàrí ìkọlù Àgọ́ ọlọ́pàá kan ní ìjọba ìbílẹ̀…
Gómìnà AbdulRazaq Rọ Àwọn Aráàlú Láti Ṣ’àtìlẹ́yìn Fún-un Bí Ọdún 2026 Ṣé Bẹ̀rẹ̀
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kwara, Àárín Gbùngbùn Àríwá Nàìjíríà, AbdulRahman AbdulRazaq, ti ké sí àwọn aráàlú láti dúró ṣinṣin nínú àtìlẹ́yìn wọn fún ìṣàkóso rẹ̀ bí ọdún 2026 ṣé bẹ̀rẹ̀.
Ó ṣèlérí pé ìjọba yóò tẹ̀síwájú nínú ìsapá rẹ̀ láti mú…
Ààrẹ Tinubu Yín Hadiza Bala-Usman Ní Ọjọ́ìbí Ọgọ́ta Ọdún
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu tí gbóríyìn fún Olùdámọ̀ràn Pàtàkì rẹ̀ lórí Ìṣètò Ìlànà àti Olórí Ẹ̀ka Ìpèsè Àpapọ̀ Àárín Gbùngbùn (CRDCU), Hadiza Bala-Usman, fún iṣẹ́ ìjọba tó tayọ̀ nígbà tó ń ṣe ayẹyẹ ọjọ́ ìbí ọgọ́ta ọdún rẹ̀.
Nínú…
Ìtọ́nisọ́nà Ṣé Pàtàkì Sí Ìgboyà Láti Darí Gẹ́gẹ́bí Aṣáájú Dáadáa – Mínísítà
Mínísítà fún Ìròyìn àti Ìtọ́sọ́nà Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Mohammed Idris, ti tẹnu mọ́ ìmọ̀ràn àti ìtọ́sọ́nà gẹ́gẹ́ bí òun pàtàkì sí ìgboyà fún ẹnikẹ́ni láti darí bí aṣáájú réré.
Mínísítà fún Ìròyìn sọ ọ̀rọ̀ yìí níbi ìpàdé kan tí…
Olóyè Pàtàkì Ni Ile Ẹjọ Gíga Jùlọ Rọ Awon Adájọ Láti Se Ìdájọ Pèlú Àánú.
Olóyè Pàtàkì ni ilé ẹjọ́ gíga jùlo ni Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Kabir Akanbi ti rọ àwọn adájọ kàkàkí Orílè-èdè Nàìjíríà láti ṣe ìdájọ pèlú Àánú lójú.
Nígbà tí o ṣe Ẹgbẹ́ àwọn adájọ ti ìlú Abuja ( NAJUC) se ìbẹ̀wọ̀ sí Akanbi ni o ti rọ wọn…
Àwọn Òṣìṣẹ́ Elétò Aláàbò Dènà Àdó Olóró Láti Du Gbámú Ni Ìpínlẹ̀ Anambra.
Àwọn elétò òṣìṣẹ́ aláàbò nì ìpínlẹ̀ Anambra ti ba ìmọ̀ àwọn ènìyàn oníṣe laabi jẹ latari bi wọn ṣe dènà àdó olóró láti bí gbámú ni ìpínlẹ̀ náà
Lásìkò tí wọn ṣe àyẹwò sí ìbi ifarapamo àwọn ènìyàn oníṣe laabi náà tó wà ni ìjọba ìbílẹ̀…
NAWOJ bẹ̀bẹ̀ fún ìrànlọ́wọ́ Hajj fún àwọn akọ̀ròyìn obìnrin
Alága obìnrin fún ẹgbẹ́ àwọn akọ̀ròyìn obìnrin ní Nàìjíríà (NAWOJ), Ẹlẹgbẹ́ Aisha Ibrahim, ti pè fún fífún àwọn akọ̀ròyìn obìnrin tí ń kọ̀ròyìn lórí ìrìn àjò mímọ́ lọ́dọọdún láyè láti darapọ̀ siṣẹ́…
Ààrẹ Tinubu kí Ayo Obe kú ọjọ́bìí pàtàkì ààdọ́rin ọdún
Ààrẹ Bola Tinubu ti ki olokiki agbẹnusọ alatilẹyin tiwantiwa ti o tun jẹ agbẹjọro, Omidan Ayo Obe, kú àjọ̀dún ọjọ́bìí ààdọ́rin ọdún.
Ile iṣẹ Ààrẹ sọ ninu alaye kan pe Aarẹ Tinubu gboriyin fun amofin naa fun iṣafihan deede fun…