Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

KÓKÓ INÚ ÌRÒYÌN

This is a category for featured story

Ayẹyẹ ayajọ IDEOF: Irin Yóò Wáyé Ni Ìlú Abuja Àti Kaduna Láti Sààmì Sí Ayajọ Ọdún Náà.

Ẹgbẹ́ tí wọn pẹ ni (BFFWH) ti sọ wí pé ayẹyẹ ayajọ ọdún yii yóò dá lórí ìrìn láàrin Ìlú Abuja àti Kaduna. Ibukun Ogundara tó jẹ agbẹnusọ fún ẹgbẹ́ náà ni o sọ èyí di mímọ̀ lásìkò to n ba àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ ni Kaduna, o ni kókó ìrin náà…

Ìpínlẹ̀ kano Buwọ́lù Lu Biliọnu Mẹta Fún Àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ Ti Yóò Ko Ìdánwò.

Ìjọba ìpínlẹ̀ Kano ti ya owó Biliọnu Mẹta sọ tọ́ láti ṣe iranlọwọ fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ti yóò ko ìdánwò NECO ni ọdún yìí. Ó ní èyí wa ni ìbámu pẹ̀lú èròngbà ìjọba ìpínlẹ̀ náà láti ṣe àtìlẹ́yìn fún ètò ẹ̀kọ́ àti ìrànlọ́wọ́ fún àwọn ènìyàn.…

Ààrẹ Tinubu ṣíṣọlójú ìgbìmọ̀ Ẹkùn, ṣàgbékalẹ̀ àwọn tó fà kalẹ̀ fún ilé ìgbìmọ̀…

Ààrẹ Bola Tinubu ti fún ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ní àkójọ àwọn orúkọ fún ìdásílẹ̀ ìgbìmọ̀ ìdàgbàsókè tuntun Árewá Àringbùngbùn, Gúsù oòrùn, àti Gúsù, tí ó sì ń bèèrè fún àyẹ̀wò àti ìfìdímúlẹ̀ wọn.…

Ẹ ṣàpọ́nlé ìṣẹ̀ǹbálẹ àwọn agbègbè tí ó gbà yín lálejò-Adarí gbogbogbòò…

Adarí gbogbogbòò fún àwọn Àgùnbánirọ̀ (NYSC), Ajagun Olakunle Nafiu, ti gba àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Àgùnbánirọ̀ nímọ̀ràn láti ṣàpọ́nlé ìṣẹ̀ǹbálẹ àwọn agbègbè tí ó gbà oníkúlukú wọ́n lálejò kí wọn ó sì jọ gbépọ̀…
button