Browsing Category
ÌRÒYÌN YÀJÓ-YÀJÓ
This is a category for TRENDING NOW
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Tẹ́lẹ̀ rí, Ọmọlolu Olunlọyọ Jáde Láyé
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti fi ikú ẹni tó ti fi ìgbà kan rí jẹ́ Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Ọ̀mọ̀wé Victor Ọmọlolu Olunlọyọ wé àdánù nlá
Makinde lo sọ ọ̀rọ̀ yìí nínù àtẹ̀jáde kan eléyìí to fi kẹ́dùn pẹ̀lú ìdílé Olunlọyọ, gbogbo ọmọ…
Adarí, Igbákejì, bẹnu àtẹ́ lu ìpànìyàn ìpínlẹ̀ Plateau
Adarí ilé ìgbìmọ̀ Aṣojú, Ọ̀gbẹ́ni Abbas Tajudeen àti Igbákejì Adarí, Ọ̀gbẹ́ni Benjamin Kalu, ti bẹnuàtẹ́ lu ìkọlù tó ṣẹlẹ̀ láìpẹ̀ yìí ní agbègbè Ruwi, Manguna, Daffo, Josho àti Hurti ní ìjọba ìbílẹ́ Bokkos ti…
Ààrẹ Tinubu dárò ikú Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ nígbà kan rí, Olunloyo
Ààrẹ Nàìjíríà, Bola Ahmed Tinubu ti ṣèdárò pẹ̀lú ìjọba àti àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Oyo lórí ikú Dókítà Victor Omololu Olunloyo, Gómìnà ìpínlẹ̀ Ọyọ àtijọ́ nígbà kan rí.
Ààrẹ Tinubu, ni orukọ Ijọba Apapọ, ti…
Ìgbòkègbodò àti àjàkálẹ̀ ààrùn kojú DR Congo
Ilé iṣẹ́ UN fún àbujútó ọ̀rọ̀ Ìṣàànú (OCHA), ti ké gbàjarì lórí bí àìláábò ṣe ń pọ̀ si ní Arewa àti Gusu Kivu lórílẹ̀-èdè Congo (DRC), níbi tí ìwà ipá ti tẹ̀sìwájú láti máa fa ìṣubú, ìpalára fún…
Nàìjíríà gba àjẹsára Men5CV láti kojú àjàkálẹ̀ ààrùn yínrùnyínrùn
Nàìjíríà ti gba òògùn àjẹsára tuntun pentavalent meningococcal alápapọ̀ pẹ̀lú (Men5CV), tí ó lé ní mílíọ́nù kan láti ilé iṣẹ́ Gavi tí ń ṣe àjẹsára lágbàáyé láti kojú àjàkálẹ̀ ààrùn tó burújàì…
Nàìjíríà ṣàlàyé pàtàkì àjọṣepọ̀ pẹ̀lú Senegal
Nàìjíríà ti ṣàpéjúwe àjọṣepọ̀ tó fìdímúlẹ̀ láàrin òun àti Senegal gẹ́gẹ́ bíi ìbáṣepọ̀ ọlọgbọ́n tó dá lórí ìtàn tí wọ́n jọ ní, iyì ìjọba tiwantiwa, àti ìdaradé ọrọ̀ ajé.
Eleyi waye lẹyin ti igbakeji Aarẹ…
Gómìnà Anambra Soludo kúnjú òsùnwọ̀n láti díje ìbò abẹ́lé Gómìnà APGA
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Anambra, Ọ̀jọ̀gbọ́n Chukwuma Soludo ti gba ìyọ̀ǹda láti ọ̀dọ̀ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Grand Alliance (APGA), láti díje ìbò abélé Gómìnà APGA tí yóò wáyé lónìí ṣíwájú ìbò Gómìnà…
Ààrẹ Tinubu ṣèdárò ikú Sẹ́nétọ̀ Otegbola
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti ṣèdárò ikú Sẹ́nétọ̀ Solomon Ayọdeji Otegbola, Asiwájú ti Ilẹ̀ Aworití ó tún jẹ́ ọ̀kan lára àgbà ìlú orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Ninu Ifiranṣẹ idaro si ẹbi Otegbola ati awọn eniyan Ilẹ Awori,…
Wike ṣèdárò pẹ̀lú Ortom lórí ikú àbúrò rẹ̀
Mínísítà Nàìjíríà fún Olú Ìlú (FCT), Ọ̀gbẹ́ni Nyesom Wike, ti ṣèdárò pẹ̀lú Gómìnà Ìpínlẹ̀ Benue nígbà kan rí, Samuel Ortom, lórí ikú ọmọkùnrin àbúrò rẹ̀, Ọgbẹni Bernard Tyozenda Ortom.
Ninu alaye kan lati…
Ìyàwó Gómìnà Èkó pè fún Àlàáfíà, Ìṣètọrẹ ànúú bí oṣù Ààwẹ̀ ṣe parí
Ìyàwó Gómìnà Èkó, Dokita Claudiana Ibijoke Sanwo-Olu ti rọ àwọn ará ìlú láti jẹ́kí ẹ̀mí Àlàáfíà, Ìṣètọrẹ ànúú, àti Ìṣọ̀kan máa báwọn gbé, bí oṣù Ààwẹ̀ ṣe parí.
Nigba ti o n ba awọn Musulumi sọrọ ni…