Browsing Category
ÌRÒYÌN YÀJÓ-YÀJÓ
This is a category for TRENDING NOW
Ààrẹ Tinubu ṣíṣọlójú ìgbìmọ̀ Ẹkùn, ṣàgbékalẹ̀ àwọn tó fà kalẹ̀ fún ilé ìgbìmọ̀…
Ààrẹ Bola Tinubu ti fún ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin ní àkójọ àwọn orúkọ fún ìdásílẹ̀ ìgbìmọ̀ ìdàgbàsókè tuntun Árewá Àringbùngbùn, Gúsù oòrùn, àti Gúsù, tí ó sì ń bèèrè fún àyẹ̀wò àti ìfìdímúlẹ̀ wọn.…
Ẹ ṣàpọ́nlé ìṣẹ̀ǹbálẹ àwọn agbègbè tí ó gbà yín lálejò-Adarí gbogbogbòò…
Adarí gbogbogbòò fún àwọn Àgùnbánirọ̀ (NYSC), Ajagun Olakunle Nafiu, ti gba àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Àgùnbánirọ̀ nímọ̀ràn láti ṣàpọ́nlé ìṣẹ̀ǹbálẹ àwọn agbègbè tí ó gbà oníkúlukú wọ́n lálejò kí wọn ó sì jọ gbépọ̀…
TIME100 Ṣèdánimọ̀ àwọn adarí Nàìjíríà méjì kan nínú ètò ìlera Àgbáyé
TIME 100 Ìlera ti ọdún 2025 ti dá orúkọ Mínísítà fún ètò ìlera àti ìwà lálàáfíà Àwùjọ, Ọ̀jọ̀gbọ́n Muhammad Ali Pate, àti Adarí fún ètò ohun jíjẹ, Ìyáàfin Ladidi Bako-Aiyegbusi.
Igbakeji Adari, eto…
Hajj 2025: Igbákejì Ààrẹ Shettima ṣe ìfilọ́lẹ̀ ọkọ̀ òfurufú alákọ̀ọ́kọ́ àwọn arìnrìn…
Igbákejì ààrẹ Kashim Shettima, ṣe ìfilọ́lẹ̀ ọkọ̀ òfurufú àwọn arìnrìn àjò Nàìjíríà alákọ̀ọ́kọ́ ti ọdún 2025, ní ọjọ́ Ẹtì ní pápákọ̀ òfurufú tí ń kẹ́rù, ti Owerri, ní ìpínlẹ̀ Imo.
Ayẹyẹ yii ṣami igbera…
Ìgbìmọ̀ Aláṣe Àpapọ̀ FEC buwọ́lu ìwé òfin tí yóò dá ìgbìmọ̀ tí ń rísí Ìṣàkóso…
Ìgbìmọ̀ Aláṣe Àpapọ̀ (FEC), tí Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu jẹ́ alága rẹ̀ ti buwọ́lu ìwé òfin tí yóò dá ìgbìmọ̀ tí ń rísí Ìṣàkóso Kòkóó (NCMB), sílẹ̀ tí èyí sì jẹ́ ìgbésẹ̀ pàtàkì láti ṣàgbéǹde ilé iṣẹ́…
Makinde Mú Ayípadà Rańpe Dé Bá Ipò Ìgbìmọ̀ Aláṣẹ Rẹ̀
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti mú ayípadà ránpẹ́ dé bá ipò àwọn ìgbìmọ̀ aláṣẹ nínú ìṣèjọba rẹ̀.
Gẹ́gẹ́ bí ìwé tí olórí àwọn òṣìṣẹ́ Gómìnà, Ṣẹgun Ogunwuyi fi síta ni ọjọ́ Ajé, (05/05/3025) ṣe fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé, Komisana fún Ohun…
Igbákejì ààrẹ Bẹ Ìpínlẹ̀ Delta Wò
Igbákejì ààrẹ Kashim Shettima ti gúnlẹ̀ sì ìlú Asaba tii ṣe Olú ìlú ìpínlẹ̀ Delta.
Ìrìn-àjò náà ní ṣe pẹ̀lú Gómìnà ìpínlẹ̀ Delta, Governor Sheriff Oborevwori to dìgbà dẹrulù rẹ̀ lọ si ẹgbẹlẹ́ òṣèlú All Progresses Congress…
CAF Kéde Àwọn igbákejì Ààrẹ tuntun níbi ìpàdé ìgbìmọ̀ Aláṣẹ
Ìgbìmọ̀ Aláṣẹ (EXCO) fún Ìgbìmọ̀ Ẹgbẹ́ Agbábọ́ọ́lù Láfíríkà (CAF) ti ṣe ìpàdé ní Accra, Ghana, ní ọjọ́ Àbámẹ́ta ṣíwájú ìfigagbága eré bọ́ọ́lù àṣekágbá àwọn ilé ẹ̀kọ́ Agbábọ́ọ́lù Láfíríkà CAF.
Aarẹ…
Igbákejì Adarí ilé pè fún àtìlẹyìn Gúsù ilà oòrùn fún àtúnyàn Ààrẹ Tinubu
Igbákejì Adarí ilé ìgbìmọ̀ Aṣojú, Ọ̀gbẹ́ni Benjamin Kalu, ti sọ pé sáà kejì tọ́ sí Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu tí a bá wo àwọn àṣeyọrí tí ó ti ṣe lórí àtúnṣe pàtàkì lórí ọrọ̀ ajé, àjọṣepọ̀ ará ìlú àti…
Mínísítà ṣe ìfilọ́lẹ̀ ilé iṣẹ́ irin Irínwó Mílíọ́nù Dọ́là ní ìpínlẹ̀ Ogun
Mínísítà Nàìjiríà fún ìdàgbàsókè Irin, Ọmọ Ọba Shuaibu Abubakar Audu, ti ṣe àjọyọ̀ ìfilọ́lẹ̀ gbangba ti ilé iṣẹ́ irin Inner Galaxy Group’s Stellar, idokowo Irínwó Mílíọ́nù Dọ́là ní ìpínlẹ̀ Ogun ní Gúsù Iwọ̀…