Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN YÀJÓ-YÀJÓ

This is a category for TRENDING NOW

Mínísítà fún ètò ìbáraẹnisọrọ̀ pinnu láti ṣàtìlẹyìn fún EFCC bí ó ṣe ìfilọ́lẹ̀ Ẹ̀rọ…

Mínísítà fún ètò ìbáraẹnisọrọ̀ àti Ìṣàlàyé, Mohammed Idris ti sọ pé ó ṣe pàtàkì fún Ìgbìmọ̀ tí ń gbógunti Ẹ̀sùn Ọrọ̀ Ajé àti Ìnáwó (EFCC), láti ràròjinlẹ̀ àti lo ọgbọ́n nípa bí wọn yóo ̀ṣe máa fi…

Ààrẹ Tinubu ṣèdárò pẹ̀lú Gómìnà Sanwolu lórí ikú olùrànlọ́wọ́ rẹ̀

Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu ti ṣèdárò pẹ̀lú ẹbí igbákejì ọ̀gá àgbà fún àwọn òṣìṣẹ́ Gómìnà Babajide Sanwo-Olu, ti ìlú Eko, Ọ̀gbẹ́ni Gboyega Soyannwo. Nini ifiranṣe idaro ti agbẹnusọ aarẹ, Ajuri Ngelale, buwọlu aarẹ Tinubu…

Nàìjíríà nílò idasilẹ àwọn Fáfítì miran fún àǹfààní àwọn ọ̀dọ́ – Adarí NUC

Akọ̀wé aláṣẹ fìdíhẹẹ́ fún ìgbìmọ̀ Fáfítì lápapọ̀, NUC, ní Nàìjíríà, Chris Maiyaki ti tẹnumọ́ pàtàkì dídá àwọn Fáfítì míràn sílẹ̀ ní Nàìjíríà nítorí bíí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ṣe ń pọ̀ si, pàápàá jùlọ…

Àwọn ilé-ẹ̀kọ́ gíga Fáfítì UK ṣe àtẹ́wọ́gbà èsì ìdánwò NECO

Adarí ìgbìmọ̀ ìdánwò àbájáde lórílẹ̀-èdè lápapọ̀ NECO, Ọ̀jọ̀gbọ́n Dantani Wushishi ti sọ pé èsì ìdánwò láti ìgbìmọ̀ náà ti rí ìgbéga bí ilé ẹ̀kọ́ gíga Fáfítì Lead àti Birmingham City ti ṣe kọ ìwé sí wọn…

Adarí Nàìjíríà ṣèlérí láti ṣàtìlẹyìn fún ààrẹ orílẹ̀-èdè Chad tí wọ́n dìbò…

Ààrẹ Nàìjíríà, Bọla Ahmed Tinubu ti fi dá ààrẹ orílẹ̀-èdè Chad tí wọ́n dìbò yàn, Mahamat Deby lójú pé Nàìjíríà yóò túnbọ̀ máa jọ ṣepọ̀ tímọ́tímọ́ pẹ̀lú orílẹ̀-èdè náà, tí ó sì ń kíi kú oríire…

Aiyedatiwa Jáwé Olúborí Gẹ́gẹ́ Bí Olùdíje Sí Ipò Gómìnà Níbí Ìdìbò Abẹ́lé Ẹgbẹ́…

Gómìnà Lucky Aiyedatiwa ti ìpínlẹ̀ Ondo ni wọ́n ti kéde gẹ́gẹ́ bí ẹni tí ó jáwé olúborí níbi ìdìbò abẹ́lé ẹgbẹ́ òsèlú APC láti yan olùdíje lábẹ́ àsìá ẹgbẹ́ náà fún ìdìbò sí ipò gómìnà tí yóò wáyé…