
Browsing Category
ÌRÒYÌN YÀJÓ-YÀJÓ
This is a category for TRENDING NOW
Ìdìbò: Ààrẹ Bùhárí gúnlẹ̀ sí ìpínlẹ̀ Katsina
Ààrẹ Mùhámmádù Bùhárì ti gúnlẹ̀ sí ìpínlẹ̀ Katsina láti dìbò gómìnà àti ti ilé ìgbìmọ̀ aṣojú ṣòfin ìpínlẹ̀ ,ọdún 2023.
Ààrẹ gúnlẹ̀ ní dédé agogo mẹ́ta kọjá ogún ìṣẹ́jú ìrọ̀lẹ́,sí pápá òfurufu…
Ìpínlẹ̀ Jìgáwá: INEC gbaradì fún ìbò gómìnà,ìgbìmọ̀ ilé aṣojú ṣòfin
Ìgbìmọ̀ olómìnira tó ń mójútó ètò ìdìbò lórílẹ̀-èdè INEC,ti sọ pé òun ti gbaradì fún ìdìbò gómìnà àti ilé ìgbìmọ̀ aṣojú ṣòfin tí kò lábààwọ́n ní ìpínlẹ̀ Jìgáwá.
Kọmiṣọna INEC ti ipinlẹ naa,…
Ààrẹ Nàìjíríà tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ dìbò yàn gbimọ ìjọba àpapọ̀ tó kúnjú òsùnwọ̀n
Ààrẹ Nàìjíríà tí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ dìbò yàn, Bọ́ĺa Tinubu, sọ pé ìpinnu tí òun ní ni láti pèsè ìjọba àpapọ̀ tó kúnjú òsùnwọ̀n,yàtọ̀ sí ti ìṣọ̀kan orílẹ̀-èdè láti gbọ́ ti ìpeniníjà orílẹ̀-èdè.
Ààrẹ tí…
Ìdìbò Gómìnà: APC, PDP fòpin sí ìpolongo ní ìpínlẹ̀ Èkó
Ẹgbẹ́ òṣèlú tó ń ṣèjọba, All Progressives Congress (APC) àti People’s Democratic Party (PDP), ní ìpínlẹ̀ Èkó ti kéde ìfòpin sí ìpolongo fún ìbò gómìnà àti ilé ìgbìmọ̀ aṣojú ṣòfin,ní ọjọ́ Àbámẹ́ta,ọjọ́…
NEMA pín àwọn oun èlò ìtura fún àwọn olùfaragbà omíyalé ní ìpínlẹ̀ Kánò
Ilé iṣẹ́ tó ń rísí ìṣàkóso pàjáwìrì lórílẹ̀-èdè (NEMA), pẹ́lú ìfọwọ́sowọ́pọ̀ ilé-iṣẹ́ tó ń rísí ìṣákóso pájáwìrí ní ìpínlẹ̀ Kánò (SEMA), ti pín àwọn ohun èlò ìtura fún àwọn olùfaragbà ìjàǹbá…
U-20 AFCON: Mínísítà fún ìdárayá gbóríyìn fún Nàìjíríà lẹ́yìn tí wọ́n gba…
Mínísítà fún ìdàgbàsókè ọ̀dọ́ àti ìdárayá, Sunday Dáre, ti gbóríyìn fún Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ́lù Flying Eagles, fún ipò kẹta tí wọ́n ṣe nínú ìdíje ife orílẹ̀-èdè Adúláwọ̀ (AFCON),U–20,ní Egypt.
Flying Eagles lu…
N kò sún sẹ́gbẹ̀ẹ́ kan fún APC o – Olùdíje gómìnà YPP Ebonyi
Olùdíje gómìnà fún ẹgbẹ́ òṣèlú Young Progressive YPP, ní ìpínlẹ̀ Ebonyi, iwọ̀ oòrùn Nàìjíríà, Dókítà Sunday Opoke ti takú pé òun kò ṣèjàǹbá ẹgbẹ́ òun o, láti ṣàtìlẹyìn fún olùdíje ipò gómìnà fún…
A le lo ẹ̀rọ alágbèéká wa fún ìkìwọ̀ ìwà ipá abẹ́lé
Ẹgbẹ́ fún ìdánilẹ́kọ̀ọ́ lórí ẹ̀tọ́ ọmọdé àti àwọn obìnrin (OPACTS), ti rọ àwọn obìnrin láti lo ẹ̀rọ alágbéká wọn gẹ́gẹ́ bí irinṣẹ́ fún ìkìwọ̀ ìwà ipá abẹ́lé.
Olùdarí aláṣẹ ti ilé-iṣẹ́ tí kìí ṣe tìjọba náà…
Arábìnrin àkọ́kọ́ ìpínlẹ̀ Sókótó pè fún ìrọ̀wọ́ rọsẹ̀ ìdìbò
Arábìnrin àkọ́kọ́ ìpínlẹ̀ Sókótó, Hajiya Mariya Tambuwal pè fún ìdìbò gómìnà àti aṣojú ṣòfin ìpínlẹ̀ nírọ̀rùn,ní ọjọ́ kejìdín-lógún,oṣù kẹta.
Ìyáàfin Tambuwal pe ìpè yìí níbi àpèjọ ìpòlongo ní…
Gómìnà Bauchi gbé Mílíọ́nù mẹ́wàá Náírà sílẹ̀ fún àwọn olùfaragbà ọjà tó jóná
Gómìnà ìpínlẹ̀ Bauchi , Bala Mohammed Abdulkadir ti kéde gbígbé iye owó Mílíọ́nù mẹ́wàá Náírà sílẹ̀ fún àwọn olùfaragbà ọjà tó jóná láìpẹ́ yìí,ní ọjà Múdà Lawal,ní ìpínlẹ̀ náà.
Muda Lawal, jẹ́…