Browsing Category
ÌRÒYÌN YÀJÓ-YÀJÓ
This is a category for TRENDING NOW
Ìpínlẹ̀ Ọyọ yóò yẹ́ ọba Olúbàdàn tó papòdà sí
Gómìnà Seyi Makinde, ti ìpínlẹ̀ Ọyọ ti sọ pé Ọba Aláyélúwà tí ó wàjà, Olúbàdàn ti ìlu Ìbàdàn, Ọba Mohood Lekan Balogun yóò gba ìyẹ́sí ìlú náà, nípa pé ìjọba yóò ri pé wọ́n ṣe ìsìnkú tó tọ́ fún un.…
Ààrẹ ẹgbẹ́ Rotary rọ Nàìjíríà láti ṣe ojú lalákàn fi ń ṣọ́rí lórí ìpadàpọ̀ ààrùn…
Ààrẹ ẹgbẹ́ Rotary Káríayé, Gordon R. McInally, ti rọ ìjọba Nàìjíríà láti ṣe ojú lalákàn fi ń ṣọ́rí ní ríri pé ààrùn rọpárọsẹ̀ kò padà wọ orílẹ̀-èdè.
McInally ki ilọ yii nigba ti o n ba awọn oniroyin ile ijọba…
Senegal : Àgbà Adarí ẹgbẹ́ alátakò búra ìṣèrànlọ́wọ́ ìborí fún ẹgbẹ́ nínú ìdìbò
Àgbà Adarí ẹgbẹ́ alátakò Ousmane Sonko ti búra láti ran ẹgbẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ jáwé olúborí nínú ìbò ààrẹ tí yóò wáyé ní ọjọ́ kẹrìnlé-lógún, oṣù kẹta, bí ó tilẹ̀ jẹ́ wípé kò gbọdọ̀ kópa, kíá ló ta mọ́…
Gómìna Oborevwori bẹnu àtẹ́ lu ìkọlù àwọn ológun, kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí àwọn olùfaragbà
Gómìna ìpínlẹ̀ Delta Gúsù Nàìjíríà, Ọ̀gbẹ́ni Sheriff Oborevwori ti bẹnu àtẹ́ lu, pípa àwọn òṣìṣẹ́ àti àwọn ọmọ ológun tó wà ní 63 Brigade, ní agbègbè Okuama, tó wà ní Agbègbè ìjọba ìbílẹ̀ Gúsù Ughelli ti…
Ààrẹ Tinubu yan Ja’afar Isa láti ṣadarí ìgbìmọ̀ Almajiri
Ààrẹ Bọla Tinubu ti buwọ́lu yíyan Ajagun fẹ̀yìntì Lawal Ja’afar Isa, ní Akọ̀wé Aláṣẹ fún ìgbìmọ̀ àwọn Àlìmájìrí lápapọ̀ àti fún ètò èkọ́ àwọn ọmọ tí wọn kò le tẹ̀síwájú lórí ẹ̀kọ́ wọn.
Ààrẹ tun buwọ́lu…
Igi Ìrókò Nlá Ti Wó: Olúbàdàn Ti Ìlú Ìbàdàn Ti Wàjà
Ọba Mohood Lekan Balogun Alli Okunmade II ti o jẹ Olubadan Kejilelogoji (42) ti waja ni alé ọjọbọ, ọjọ́ kẹrinla, Oṣù Kẹta, Ọdún 2024.
Ile Iwosan UCH niluu Ibadan lo dakẹ si
Ọmọ Ọdun mọkanlelọgọrin (81) ni Olubadan Lekan Balogun ki o…
Ìbò Senegal: Gambari yóò darí àwọn awòye ECOWAS
Ọ̀jọ̀gbọ́n Ibrahim Gambari ni yóò darí àwọn ikọ̀ awòye ECOWAS fún ìbò ààrẹ Senegal, tí yóò wáyé ní ọjọ́ kẹrìnlé-lógún, oṣù kẹta, ọdún yìí.
Kọmiṣọna ECOWAS fun ọrọ oṣelu, Alaafia, ati Aabo, Aṣoju Abdel-Fatau Musah,…
Àwọn oníròyìn obìnrin ṣàjọyọ̀ Àyájọ́ Àwọn obìnrin Káríayé
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ àwọn obìnrin Akọ̀ròyìn ní Nàìjíríà (NAWOJ, ti ikọ̀ FCT ti ró àwọn obìnrin tó ju igba lágbára lọ ní ààfin Nga’Kupi Sa’peyi, ní Garki Village, Abuja, gẹ́gẹ́ bí ayẹyẹ láti ṣàmì Àyájọ́ àwọn obìnrin…
Ìpínlẹ̀ Kwara : Ẹgbẹ́ ra fọ́ọ̀mù JAMB Fún àwọn ẹgbẹ̀rún méjì akẹ́kọ̀ọ́ tí kò lówó láti…
Ẹgbẹ́ Amana ti ra fọ́ọ̀mù ìdánwò láti wọ ilé ìwé gíga Fáfítì (JAMB) Fún àwọn ẹgbẹ̀rún méjì akẹ́kọ̀ọ́ tí kò lówó láti ràá ní ìpínlẹ̀ Kwara, Àríwá Àringbùngbùn Nàìjíríà.
Alaṣẹ Adari National Institute…
Ìṣèfilọ́lẹ̀ Isẹ́ Àkànṣe: Ìpínlẹ̀ Niger yóò gbàlejò ààrẹ Tinubu
Ìjọba ìpínlẹ̀ Niger ní Àríwá Àringbùngbùn Nàìjíríà ti parí ìpalẹ̀mọ́ fún ìṣàbẹ̀wò ààrẹ Ahmed Bọla Tinubu ní ìrọ̀rùn, fún Ìṣèfilọ́lẹ̀ ẹ̀rọ ọhun ọ̀gbìn tí wọ́n rà, tí ó tó Bílíọ́nù Náírà, nínú àwọn…