Browsing Category
ÌRÒYÌN YÀJÓ-YÀJÓ
This is a category for TRENDING NOW
Ẹgbẹ́ ṣe àgbékalẹ̀ àyẹ̀wò jẹjẹrẹ ọyàn fún àwọn obìnrin ní FCT
Nínú akitiyan láti ṣàgbélárugẹ ìlera àti ìwà lálààfíà àwọn obìnrin, MamaJazzYard Charity Foundation ti ṣe àgbékalẹ̀ àyẹ̀wò jẹjẹrẹ ọyàn fún àwọn obìnrin méjelé-nígba láti àwọn agbègbè tí wọn kò ti ní…
Wọ́n dojú ìjà kọ Dókítà mẹ́rìndín-láàdọ́jọ ní ọdún méjì- Ìjábọ̀ fihàn
Ìjábọ̀ kan láìpẹ́ yìí láti ọ̀dọ̀ ẹgbẹ́ àwọn Dókítà Nàìjíríà ti fihàn pé lápapọ̀ ẹ̀sùn ìdojú ìjà kọ àwọn Dókítà mẹ́rìndín-láàdọ́jọ ni wọ́n ti gbà sílẹ̀ láti ọjọ́ kínní, oṣù kínní 2022 sí ọjọ́…
Ọmọ orílẹ̀-èdè Faranse, Mbappe yóò mọ bí ọjọ́ iwájú yóò ṣe rí kó tó di àsìkò Euros
Ògbóhùntarìgì Agbábọ́ọ́lù Paris St Germain, Kylian Mbappe ti sọ pé òun nígbàgbọ́ pé òun yóò mọ ilé agbábọ́ọ́lù tí ó kàn fún òun láti darapọ̀ mọ́ fún sáà tí ń bọ̀ kí ó tó di àsìkò tí ìfigagbága àwọn…
Kwara: Gómìnà AbdulRazaq ṣàdárò ìpapòdà Ọba ìlú Oro
Gómìnà ipinlẹ Kwara, ní Àríwá Àringbùngbùn Nàìjíríà, AbdulRahman AbdulRazaq, ti darapọ̀ mọ́ àwọn ará ìlú Oro láti ṣèdárò ìpapòdà Ọba Aláyélúwà, Oloro ti ìlú Oro, HRM Ọba AbdulRafiu Olaniyi Ajiboye Oyelaran…
Gómìnà Kano gbóríyìn fún ààrẹ Tinubu Fún bí ó tún ààlà Nàìjíríà-Niger ṣí
Gómìnà ìpínlẹ̀ Kano ní Àríwá iwọ̀ oòrùn Nàìjíríà, Abba Kabir Yusuf, ti gbóríyìn fún ààrẹ Tinubu fún bí ó ti padà ṣí ààlà Nàìjíríà-Niger, tí ó sì sọ pé yóò jẹ́ kí ìpọ́njú dínkù tí yóò sì tún…
Ìjọba Nàìjíríà túnbọ̀ fìdí ìpinnu rẹ̀ múlẹ̀ lórí ìgbé ayé àlàáfíà fún àwọn…
Adájọ́ Àgbà lápapọ̀ fún Nàìjíríà tí ó tún jẹ́ Mínísítà fún ètò Ìdájọ́, Lateef Fagbemi, SAN ti túnbọ̀ fìdí ìpinnu ìjọba àpapọ̀ múlẹ̀ lórí bí ó ṣe pàtàkì ìgbé ayé àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba nípasẹ̀ sísan…
Fagbemi rọ àwọn Àlùfáà Mùsùlùmí láti gbàdúrà fún Nàìjíríà
Adájọ́ Àgbà lápapọ̀ fún Nàìjíríà tí ó tún jẹ́ Mínísítà fún ètò Ìdájọ́, Agbẹjọ́rò Lateef Fagbemi, ti rọ àwọn adarí ẹ̀sìn láti máa ṣàdúrà fún ìjọba tó wà lórí oyè lábẹ́ ìṣàkóso ààrẹ Bọla Ahmed…
Ilé ìgbìmọ̀ Anambra ṣe ìpàdé ní ìdágbére fún Adarí ilé nígbà kan rí, Nnebe tí ó di…
Ilé ìgbìmọ̀ Anambra ní ọjọ́ Ẹtì ṣe ìpàdé ìdágbére ní ìyẹ́sí adarí ilé tẹ́lẹ̀, Ọ̀gbẹ́ni Anayo Nnebe, tí ó di olóògbé ní ọjọ́ kẹtàlé-lógún, oṣù kínní, ní ọmọ ọdún mọ́kànlé-lọ́gọ́ta.
Nnebe jẹ Adari ile…
NCDC fi ìdí ogún ikú Ibà Lassa múlẹ̀ ní ìpínlẹ̀ mẹ́rìndín-lógún
Ilé Iṣẹ́ tí ń ṣe àmójútó àti ìdènà àjàkálẹ̀ ààrùn ní Nàìjíríà (NCDC), ti sọ pé àwọn ènìyàn míràn tún ti kó ààrùn Lassa tí ààrùn náà sì ti gbẹ̀mí ogún ènìyàn jákèjádò ìpínlẹ̀…
Ibà Lassa : Delta fìdí mẹ́rin múlẹ̀
Ìjọba ìpínlẹ̀ Delta ti fìdí ààrùn Ibà Lassa mẹ́rin múlẹ̀ ní ìpínlẹ̀ náà tí ó sì ń rọ àwọn olùgbé láti jẹ́ kí agbègbè wọn wà ní mímọ́ nígbà gbogbo.
Dokita Joseph Onojaeme, Kọmiṣọna fun eto ilera ti ipinlẹ…