Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Yobe Rán Àwọn Onímọ̀ Nípa Àìsàn Kídìnrín Láti Ṣe Íwáàdí.
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Yobe ti ran àwọn onímọ̀ ìjìnlè nípa àìsàn Kidinrin láti ṣe ìwádìí nipa ohun tí o fá àìsàn Kidinrin ni àwọn agbègbè kan ni ìpínlẹ̀ náà.
Dọ́kítà Mahmud Maina to jẹ adarí àgbà ní ilé ìwé ìwòsàn Biomedical Science Research…
Àwọn Onímọ̀ Nípa Àìsàn Suger Sọ Wí Pé Ẹja Funfun Dára Fún Ìlera Ará Wọn.
Onímọ̀ nípa àìsàn Suger Dọ́kítà Ayuba Mugana pẹ̀lú ilé ìwòsàn Abubakar Tarawa ni ìpínlẹ̀ Bauchi tí gbà àwọn ènìyàn tó ni àìsàn Suger lamoran láti túnbọ̀ ma eja Funfun fún Àlàáfíà agọ ará wọn.
Ó gbà wọn lamoran yìí nìgbà tí wọn fi ọrọ wá…
Àjọ UNICEF Pàrọwà Sí Àwọn Adarí Ìpínlẹ̀ Kano Láti Mú Ìgbòòrò Bá Àjẹsára Àwọn…
Àjọ UNICEF ti pàrọwà sí àwọn ọba alayé àti alákòsóo ìjọba ìbílẹ̀ gbogbo láti mú ìgbòòrò bá abẹ́rẹ́ àjẹsára àwọn ọmọdé èyí tí yóò dènà àrùn ní papàá jùlọ àrùn rọpá-rọsẹ̀
Priyanka Khanana…
Olùdarí Ilé Aṣòfin Èkó Ti Pé Fún Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Láti Fòpin Sí Dídá Abẹ́ Fún Ọmọbìnrin
Olùdarí Ilé Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Ìpínlẹ̀ Èkó, Aṣòfin Mojísọ́lá Maranda ti pé fún ìfọwọ́sowọ́pọ̀ láti fòpin sí dídá abẹ́ fún ọmọbìnrin
Nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ nínú ayẹyẹ ìsàmì àyàjọ́ ìfòpinsí Dídá Abẹ́ fún Ọmọbìnrin Lágbàáyé ti ọdún 2025,…
Ìdèra Dé: Àwọn Ènìyàn Ìpínlẹ̀ Cross River Jẹ Ànfààní Ìwòsàn Ọ̀fẹ́
Kò dín ní ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ènìyàn tí ó jẹ ànfààní ìwòsàn ọ̀fẹ́ fún oníran-ìran àìsàn èyí tí àjọ kan tí ìgbáyégbádùn ọmọnìyàn jẹ lógún se agbátẹrù rẹ̀
Àwọn olùgbé àgbègbè náà, àgbàlagbà,…
Ìgbìmọ̀ Ìjọba Àpapọ̀ Buwọ́lu Ọ̀bítíbitì Owó Láti Mú Ìgbòòrò Bá Ẹka Ìwòsàn Àti…
Ìgbìmọ̀ Ìjọba Àpapọ̀ buwọ́lu owó tí ó tó bílíọ̀nù kan dọ́là lé díẹ̀ fún ìdàgbàsókè ẹka ìlera, èyí tí yóò mú ìdàgbàsókè aláìlẹ́gbẹ́ bá ètò ìlera fún ànfààní mùtú-mùwà
Ní àfikún, ìjọba…
Àyájọ́ Àìsàn Jẹjẹrẹ: Mínísítà Pèpè Ìrànlọ́wọ́ Fún Àwọn Tí Ó Lùgbàdì Àrùn
Mínísítà Fún Ọ̀rọ̀ Àwọn Obìnrin ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Hajiya Imaan Sulaiman-Ibrahim ti darapọ̀ mọ́ awọn ènìyàn ní Orílẹ̀-èdè àgbáyé gbogbo fún àyájọ́ àìsàn jẹjẹrẹ níbi tí o tí fi àrídájú àtìlẹyìn…
NTDs: Adarí gbogbogbòò NITR rọ àwọn tó nííṣe láti ṣàtúnṣe lórí ìnáwó
Adarí gbogbogbòò ti ilé iṣẹ́ tí ń ṣe ìwáádí Trypanosomiasis (NITR), Joachim Ajakaiye ti rọ ìjọba àpapọ̀ àti àwọn tó nííṣe láti wá owó ṣètò ìjàfita fita Nàìjíríà láti gbógunti àwọn ààrùn inú igbó tí wọ́n…
Kọmíṣọ́nà fún ètò ìlera Anambra pinnu ìtọ́jú alábọ́ọ́dè, tósì tún múná dóko
Kọmíṣọ́nà fún ètò ìlera ní ìpínlẹ̀ Anambra, Dokita Afam Obidike, túnbọ̀ fìdí ìpinnu ìjọba ìpínlẹ̀ múlẹ̀ lórí ìpèsè ètò ìtọ́jú tó wà lárọwọ́tó, tí owó rẹ̀ kò sì tún ní jara lọ fún àwọn ará ìlú níbi…
Ìpínlẹ̀ Sokoto Ní Yóò Gbàlejò Àwọn Ilé ìwé Gíga Nípa Ètò Ìlera.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Sokoto Ahmed Aliyu ti so wí pé ohun ṣetán láti Gbàlejò ìdánilékòó ọdọọdún fún àwọn ilé ìwé nípa ètò ìlera èyí tí yóò wáyé ninu osù kẹsán ọdún 2025.
Lásìkò tí o ṣe àbẹ̀wọ̀ sí Ààre NPMCM ọ̀mọ̀wé peter Ebeigbe , Gómìnà dupe…