Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
Ẹgbẹ́ Bèrè Fún Ìrànlọ́wọ́ Ìjọba Fún Ìdàgbàsókè Àwọn Ilé ìwòsan Ní Ìpínlẹ̀ Kogi.
Ẹgbẹ́ àti àwọn tọrọ kàn ni àwọn ilé ìwòsan to pàtàkì ni ìpínlẹ̀ Kogi ti pé fún ìrànlọ́wọ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Kogi láti ṣe àtìlẹ́yìn fún àwọn ilé ìwòsan ìjọba ni ìpínlẹ̀ náà.
Wọn rawọ́ ẹ̀bẹ̀ náà lásìkò tí wọn ṣe àbẹ̀wọ̀ sí Adarí àgbà pátápátá…
Àjọ FAO Se Ìrànlọ́wọ́ Fún Ẹgbẹ̀rún Àwọn Ògo Wẹẹrẹ Ní Ìpínlẹ̀ Sokoto
Ọgbẹ́ni Koffy Dominique tí ó ń sojú fún àjọ FAO tí àgbáyé ní Orílẹ̀-èdè ECOWAS àti Nàìjíríal ni ó fi ọ̀rọ̀ léde pé àjọ náà ti gbé ìgbésẹ̀ akin láti rí i dájú pé ìsòro ebi di àfìsẹ́yìn tí egúngún ń…
Nípa Ẹ̀sùn Ìfipábánilòpọ̀: Omidan Felicia Rawọ́ Ẹ̀bẹ Fún Ìdájọ́ Òdodo
Omidan Felicia Ogbonna, tí ó jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélógún ti rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ìjọba léyìí tí ó bèrè fún ìdájọ́ òdodo látàrí fífi ipá bá a lòpọ̀, èyí tí ó wáyé láti ọwọ́ onísòwò ńlá tí ó fi ìlú Èkó se…
Ẹgbẹ́ Aláàdáni Bèrè Fún Àtìlẹ́yìn Nípa Àwọn Tó Ni Àìsán Autism.
Ẹgbẹ́ Aláàdáni tí wọn pẹ ni (SUNDAYI) ti Victoria Jim jẹ aṣojú fún ti bere fún atilẹyin àti ìrànlọ́wọ́ fún àwọn ọmọ tó ni àìsàn Autism.
Ó sọ èyí di mímọ̀ ni ìlú Abuja nígbà tí wọn ṣe ìpàdé, wọn sàlàyé pàtàkì tí o wa nínú ìbáṣepọ̀ pẹ́lù…
Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Àti Ilé Iṣé Aláàdáni Yóò Ni Ìbáṣepọ̀ Láti Mú Ìdàgbàsókè Ba Ilé Ìwòsàn…
Ìjọba àpapọ̀ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí buwolu ìwé ìbáṣepọ̀ láàrin ilé ìwòsan ìjọba National Hospital ti Abuja àti ilé ìwòsan aláàdáni merin míràn láti mú ìdàgbàsókè ba ètò ìlera Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Nígbà tí o n sọrọ níbi ayẹyẹ náà Mínísítà…
Ìpínlẹ̀ Abia: Àjọ SCIAN Pín Kẹ̀kẹ́ Alábọ̀ara Fún Ọmọ Ẹgbẹ́
Àjọ Spinal Cord Injury Association of Nigeria (SCIAN), ẹka ti Ábíá ti gbé Kẹ̀kẹ́ Alábọ̀ara fún ọmọ ẹgbẹ́ ti ṣe ọmọ ìlú wọn, ọgbẹni Francis Ukpai fún ìrìn rẹ̀.
Alaga àjọ SCIAN, ọgbẹni David Onuoha,sọ pé àwọn ọmọ ẹgbẹ ṣe ìkówójọ náà ní…
Àìsàn Inú Àti Ọ̀fun: Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ti Pàdánù Àwọn Ènìyàn Tó Lẹ Ni Ọgọrùn Látàrí Abẹ́rẹ́…
Àjọ tó n mójú tó ètò ìlera ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà NCDC, sọ wí pé àwọn ènìyàn tó lẹ́ ni ọgọrùn ni o ti pàdánù emi wọn látàrí àìsàn to n ba inú àti Ọ̀fun jà èyí to n ṣẹlẹ báyìí nì Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.
Àjọ NCDC sọ èyí di mímọ̀ nígbà tí wọn…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Ebonyi Gbégbá Orókè Nípa Ètò Ìlera- Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ Gbósùbà Fún Ìjọba
Alága Ẹgbẹ́ àwọn elétò ìlera ẹka ti ìpínlẹ̀ Ebonyi, Chetachi Usulor ti gbósùbà fún gómìnà Ìpínlẹ̀ Ebonyi, Francis Nwifuru látàrí akitiyan rẹ̀ lórí ìdàgbàsókè ètò ìlera ní ìpínlẹ̀ náà
Usulor lu…
Ẹ Wà Ní Ojú Ni Alákàn Fi Ń Sọ́rí Gẹ́gẹ́ Bí Àjọ NCDC Se Sàwárí Àrùn Ibà Lassa
Àjọ NCDC ti sàwárí àrùn ibà Lassa láti ara akọhṣẹ́mọṣẹ́ oníṣègùn òyìnbó ẹni ọdún mọ́kànlélọgbọun kan tí ó ṣẹ̀sẹ́ dé láti Orilẹ-ede United Kingdom
Dokita Jide Idris ni ó síṣọ lóju ọrọ naa nígbà ti o n…
Ọ̀fẹ́ Ní Ìtọ́jú Àrùn HIV Ní Ilé Ìwòsàn Ìjọba Gbogbo- Àjọ NACA Fìdí Ọ̀rọ̀ Múlẹ̀
Àjọ NACA sàpèjúwe ìròyìn kan tí ó ń jà káàkiri orí ẹ̀rọ ayélujára gẹ́gẹ́ bí ìròyìn òfegé èyí tí ó sọ pé ìjọba tí yọwọ́ ìrànwọ́ rẹ̀ kúrò lórí ìtọ́jú àìsàn HIV
Adarí àpapọ̀ fún àjọ…