Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
Ẹgbẹ́ Tó Mójú Àisìán Jẹjẹrẹ Bẹ̀rẹ̀ Fún Itọju Àisìán Náà Lábẹ́ Ètò NHIA.
Ààrẹ Ẹgbẹ́ tó ṣe ìtọ́jú àisìán jẹjẹrẹ, Dọ́kítà Adamu Umar ti ké sí Ìjoba Àpapọ láti jẹ ki àwọn ènìyàn tó ní àisìán jẹjẹrẹ máa gba ìtọjú labẹ itọju NHIS.
Umar sọ èyí di mímọ nígbà tí o n ba àwọn oníròyìn sọrọ ní ìlú Abuja, nibi ayajọ…
Ẹgbẹ́ Àwọn Àfin Fẹ́ Àtìlẹyìn Ìjọba Láti Gbógun Ti Àìsàn Jẹjẹrẹ
Àjọ Albinism Association of Nigeria (AAN) ti pè fún àtìlẹyìn láti ọ̀dọ̀ ìjọba láti dènà àrùn jẹjẹrẹ fún àwọn ènìyàn tó jẹ àfín nítori ìpènijà ti àwọn ẹ̀dá bẹ́ẹ̀ má ń dojúkọ wọ́pọ̀.
Ààrẹ àjọ AAN, Iyaafin Bisi Bamishe lo pe…
INEC dá ìbò àdìkù dúró ní àwọn agbègbè ìpínlẹ̀ mẹ́ta
Ìgbìmọ̀ olómìnira tí ń mójútó ètò ìdìbò lórílẹ̀-èdè, INEC ti kéde ìdádúró àwọn ìdìbò àdìkù tí ń lọ lọ́wọ́ ní àwọn agbègbè kan nítorí ìdàrú, àìsedédé àti jíjí àwọn òsìṣẹ́ elétò ìdìbò…
Àyè Ti Sí Sílẹ̀ Fún Gbígba Àwọn Òsìṣẹ́ Elétò Ìlera- Ìjọba Àpapọ̀
Lójúnà àti wá ojútùú sí ìsòro àdíkù àwọn òsìṣẹ́ elétò ìlera ní Orílẹ̀-èdè àti mímú ìgbòòrò bá ètò ìlera, ìjọba àpapọ̀ ti fi àyè sílẹ̀ fún ìgbàwọlé àwọn òsìṣẹ́ elétò ìlera kí ìtọ́jú tí ó…
NIDCOM Pè Fún Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Àwọn Dókítà Onímọ̀-Ìṣègùn Òyìnbò Tí Ó Wà Ní…
Alákòóso àwọn Ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ó wà ní òkè òkun, Abikẹ Dabiri-Erewa ti pè fún ìfọwósowọ́pọ̀ àwon dókítà onímọ̀ ìsègùn òyìnbó tí ó wà ní òkè òkun, kí wọn sì kó ipa rere lójúnà àti mú…
Ìjọba Àpapọ̀ Ń Siṣẹ́ Takun-takun Láti Mú Ìgbòòrò Bá Ètò Ìlera- Mínísítà
Mínísítà kejì Fún Ètò Ìlera, Dókítà Tunji Alausa ti sàlàyé ìpinnu ìjọba àpapọ̀ láti rí i dájú pé ìdàgbàsókè dé bá ètò ìlera léyìí́ tí yóò máa pawó wọlé fún ìjọba gẹ́gẹ́ bí ó se ń wáyé ní…
Ẹgbẹ́ Ṣe Ètò Àyẹ̀wò Fún Àwọn Ti Ìṣẹ̀lẹ̀ Ìfipábánilòpọ̀ Ṣẹlẹ Sí Rí.
Ẹgbẹ́ ti wọn pè ní CSO àti ASSH Foundation ti ṣe ètò àyẹ̀wò ọ̀fẹ́ fún àwọn ènìyàn tí ìṣẹ̀lẹ̀ ìfipábánilòpọ̀ ṣẹlẹ̀ sí rí fún àtúnṣe.
Adari ètò náà Ọgbẹni Kingsley Yalling lo sọ èyí di mímọ nínú ìfòròwánilénuwò ní ọjọ́rú , Ó sọ wí pé àyẹwò…
Ilé Ẹkọ Gíga FUT Sí Gbọgán Ààbò Ati Ìtọ́jú Oúnjẹ Sí Ilé Ẹ̀kọ́ Náà
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Niger tí ṣe àfihàn àrídájú ìbáṣepọ̀ rẹ pẹ̀lú ilé ìwé gíga FUT láti rí wí pé ètò ẹ̀kọ́ nípa oúnjẹ wa ni Ìdàgbàsókè ni ìpínlẹ̀ náà.
Gómìnà sọ èyí di mímọ nígbà tí o n sí àwọn Gbọgán fún ìtọ́jú àti ààbò lórí ounjẹ èyí tí…
Dí dènà Àìsàn Rọmọlápá: Àjọ UNICEF Ṣe Ìrànlọ́wọ́ Gbọgán, Ọkọ̀ Tuntun Fún Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kebbi
Àjọ UNICEF ti ṣe Iranlọwọ gbọgán àti ọkọ̀ tuntun Ajọ́kẹ́lẹ́ merin fún ilé ìwòsàn ijoba ti ìpínlẹ̀ Kebbi.
Nígbàtí o n sọ̀rọ̀ níbí ayẹyẹ náà Gómìnà Nasir Idris gbóríyìn fún Àjọ UNICEF fún ìrànlọ́wọ́ nla yìí eyi ti wọn ṣe fún ìpínlẹ̀ náà…
Ìjọba ìpínlẹ̀ Eko, Chinese ṣe iṣẹ́ abẹ ojú ọ̀fẹ́ fún àwọn ọmọdé
Ilé iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ tí ń mójútó ètò ìlera ti ìpínlẹ̀ Eko àti Aṣojú orílẹ̀-èdè China ti ṣe iṣẹ́ abẹ ojú ọ̀fẹ́ fún àwọn ọmọdé mẹ́jọ láti dènà ojú fífọ́.
Akọwe gbogbogboo, ti Ilé iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ tí ń…