Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
Àyájọ́ Àisìán Wárápá: Àjọ Ìlera Lágbayé Ṣe Àtìlẹ́yìn Láti Jẹ Kí Àwọn Ènìyàn Ni Ìmòye Nípa Àìsàn Naa.
Ni igbiyanju lati dẹkùn àìsàn wárápá àjọ àgbáyé fún ìlera bo síta fún ìkéde ìmòye lórí àìsàn náà fún ọdún 2024
Àkọlé ti ọdún yìí ni Àìsàn wárápá imọlẹ fún ìmòye lórí rẹ.
Àjọ ìlera àgbáyé n gbìyànjú láti rí wí pé àwọn ènìyàn ni ìmòye…
Àwọn Tọ́rọ̀ kàn Fi Ẹ̀dùn Ọkàn Wọn Hàn Lórí Bi Àìsàn Ìfọ́jú Ṣé Ń Pósí Ní Ìpínlẹ̀ Plateau.
Àwọn tọrọ kàn ni ti ètò ìlera ni ìpínlẹ̀ Plateau tí fí ẹ̀dun ọkàn wọn hàn bi àisìán ojú fifọ ṣe n pósí ni náà to sì n jasi iṣẹ́ abẹ.
Níbi Ìpàdé tí ẹgbẹ́ tó n mójú tó ọ̀rọ̀ ojú (RAAB) gbé kalẹ ní Jos ni àwọn tọrọ kàn ti sọ èyí jáde.…
Àwọn Òṣìṣẹ́ Nọ́ọ́sì Àti Agbẹ̀bí Ṣe Ìwọ́de Nílùú Abùjá
Ètò ìlànà tuntun tí ẹgbẹ́ àwọn òṣìṣẹ́ nọ́ọ́sì àti agbẹ̀bí orílẹ̀ èdè Nàìjíríà gbé jáde pé òṣìṣẹ́ nọ́ọ́sì àti agbẹ̀bí tó bá fẹ́ gba isẹ́ ní òkè òkun gbọ́dọ̀ tí lẹ se iṣẹ́ fún ọdún méjì gbáko, kí ó sì tún ni ìwé ẹ̀rí moyege nipa rẹ̀.…
Àisìán Ọkàn: Ìyàwó Gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra Pé Fún Àyẹ̀wò Nígbà Gbogbo
Ìyàwó Gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra, Ìyáàfin Nonye Soludo, sọ wí pé ìṣòwò ti àisìán Ọkàn ṣe n gbilẹ̀ lásìkò yii, o yẹ kí àwọn ènìyàn ma lọ fún àyẹwò nígbà gbogbo.
Nigba ti o n sọrọ ní Awka, ìyàwó Gómìnà ni, o ṣe ni lanu wí pé àwọn ènìyàn kò ka…
Àwọn Ènìyàn Ìpínlẹ̀ Èkó Fi Ariwo Ta Látàŕi Òògùn Ìdáàbò Bò Lásìkò Ìbálòpọ̀…
Àwọn ènìyàn ìpínlẹ̀ Èkò ti ké gbàjarè látàrí òògùn ìdáàbò bò tí ó gbówó lórí èyí tí ó le è fa ìtànkálẹ̀ àrùn àti àìrò-tẹ́lẹ̀ oyún
Níbi ìfọ̀rọ̀-wáni-lẹ́nu -wò tí ó wáyé ní àwọn…
GBV: Ipinlẹ Adamawa, Àjọ UNICEF Kọ́ Ẹgbẹ̀rún lé Ọ̀tàlélúgba Ọ̀dọ́ Ní Ẹ̀kọ́
Ọ̀gá fún ọrọ ọdọ àti ẹ̀kó lori ìlera àti Ibalopọ ni ipinle náà, Hajiya Fadimatu Hamman-Joda, lọ sọ eyi nibi ìfòròwánilénuwò ni ilu Yola, ó sọ pé gbogbo awọn akopa ni won yan jakejado mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n lé nígba wọ́ọ̀dù ti o wa ni…
Obìnrin Ẹni Odún Méjìlélọ́gọ̀ta Bímọ Ní Ìlú Èkó
Obìnrin Ẹni Odún Méjìlélọ́gọ̀ta , Iyaafin Fummi Akinade ti bimo okunrin ni alaafia ni ilu Eko leyin ọdún mọkanlelọgbọ̀n to ti se igbeyawo lai sí ọmọ.
Ètò ni ti Igbalode, Vitro Fertilisation (IVF), àti ìṣe abe lọ fi bímọ ni ile…
Ọjọ́ Gbogbo Ni Ti Olè, Ọjọ́ Kan Ni Ti Olóhun: Ìjọba Ìpínlẹ̀ Anambra Sàwárí Ayédèrú Ilé…
Ìjọba ìpínlẹ Anambra ti nawọ́ gán olùdarí ayédèrú ilé ìwòsàn kan tí ó ń ta àwọn ọmọdé jòjòló tí ó wà ní nọ́ḿbà alákọ̀kọ́ọ́ òpópónà Tansian Yunifasiti, Umunya, ìjọba ìbílẹ̀ Oyi, ìpínlẹ̀ Anambra
…
Ó Se Pàtàkì Kí Òfin Tí Yóò Dènà Dídábẹ́ Fún Ọmọbìnrin Wáyé- Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ Kan…
Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ Dókítà Onímọ̀ Ìsègùn Òyìnbó, Nathaniel Adewọle ti Yunifásitì ìlú Abuja, Gwagwalada ti pè fún síṣe àgbékalẹ̀ òfin èyí tí yóò dènà dídábẹ́ fún àwọn ọmọdébìnrin ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà…
Ọ̀pọ̀ Àwọn Ìwé Ẹ̀rí Láti Fi Ran Ògùn Wọlé So Orílẹ̀-èdè Yìí Ló Jẹ Ayédèrú:Ajo NAFDAC.
Àjọ to ń mójú tó ọ̀rọ̀ óúnje ati ògùn ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NAFDAC) jẹ ko di mímọ̀ wí pé ilaji nínú àwọn ìwé ẹ̀rí láti fi rán ògùn wole Si Orílẹ̀-èdè ni o jẹ ayédèrú.
Èyí di mímọ lati enu ọ̀mọ̀wé Mojisola Adeyeye to jẹ Adari àgbà…