Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
Ọ̀gá Àgbà pátápátá Fún i NPHCDA Ti Pé Fun Akiyesi Pàtàkì Lori Àìsàn Ọpọlọ.
Ọ̀gá àgbà pátápátá fún àwọn ilé ìwòsàn ìjọba, Dọ́kítà Muyi Aina ti rọ àwọn ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti ní àkíyèsí pàtàkì nipa àìsàn tí o n ba ọpọlọ já tí wọn n pé ni Meningitis.
Ó ní nípa ṣíṣe àkíyèsí yìí ni àsìkò yóò mú kí ìtọjú wà, a…
Àìsàn Ibà Lassa Pa Ènìyàn Mẹ́wàá Ní Ìpínlẹ̀ Ebonyi
Elétò ìlera ìpínlẹ̀ Ebonyi ti kéde pé ibà Lassa ti pa ènìyàn mẹwa lati ọjọ kerin sí ọjọ kẹrindinlogun oṣù keji ọdún 2024. Olùtọpinpin àìsàn fún Minisiri náà, ọgbẹni Sampson Orogwu,ló fi èyí lede ninu akọsilẹ ni ilu Abakaliki.…
Ẹgbẹ́ Kan Pín Ẹsẹ̀ Àtọwọ́dá Fún Àwọn Tí Ẹsẹ̀ Wọn Ti Gé Dànù Ní Ìpínlẹ̀ Anambra
Foundation Distributes Artificial
Ẹgbẹ́ Agocares Foundation for Persons with Disabilities ti so pe ètò ti wa nile lati pin ẹse àtọwọ́dá ọ̀fẹ́ ọ̀dúnrún fún àwọn ti ẹsẹ̀ wọn ti ge ni ipinle Anambra láti le jẹ ki wọ́n máa rìn…
Ètò Ti Parí láti Se Ìrànlọ́wọ́ Fún Àwọn Tí Ó Ní Ìpèníjà Àrùn Kògbóògùn HIV Ní…
Àjọ aláàánú ọmọnìyàn kan pẹ̀lú ìfọwọ́sowọ́pọ̀ ìjọba ìpínlẹ̀ Anambra ti sàgbékalẹ̀ ètò kan láti se ìrànlọ́wọ́ fún àwọn tí àìsàn HIV ń bá á fínra ní ìpínlẹ̀ Anambra pẹ̀lú àwọn òògùn tí ó wúlò fún…
Àjọ Kan Se Ìdánilẹ́kọ̀ọ́ Lórí Àìsàn Jẹjẹrẹ Ẹpọ̀n
Àjọ kan tí kì í se ti ìjọba ti pè fún ìfọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àjọ ìbílẹ̀ kan láti se ìdánilẹ́kọ̀ọ́ èyí tí yóò gbógun ti àìsàn jẹjẹrẹ ẹpọ̀n
Olùdásílẹ̀ àjọ náà, Dokita Zainab-Shinkafi Bagudu sàlàyé…
Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ Sèkìlọ̀ Nípa Ìtànkálẹ̀ Àìsàn Ọkàn Látàrí Òtútù Tí Ó Gbalé-gboko
Ọ̀jọ̀gbọ́n Basil Okeahialam ti sèkìlọ̀ wípé òtútù tí ó mú ní àwọn àgbègbè kan ní Orílẹ̀-èdè le è kó ìpalára bá ọkàn, tí kò bá sí àmójútó tí ó péye
Okeahialam tí ó jẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n ní Yunifásitì…
Dójú tòfò ìlera: Ẹgbẹ́ bẹ̀rẹ̀ ìforúkọ àwọn olóyún sílẹ̀ ní Ebonyi
Ẹgbẹ́ tí kìí ṣe tìjọba kan, Ẹgbẹ́ Ìlera tó dára fún àwọn obìnrin ìgbèríko, àwọn ọmọdé àti àwọn tí wọ́n fipá ṣí nípò ti bẹ̀rẹ̀ sí ní fi orúkọ àwọn olóyún sílẹ̀ ní ilé iṣẹ́ dójú tòfò ìlera ti ìpínlẹ̀…
Aṣòfin Ilé Ìgbìmọ̀ Ṣe Ètò Ìtọ́jú Ọ̀fẹ́ Fún Àwọn Ènìyàn Ẹgbẹrun Kàn Àbọ̀.
Aṣojú ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin tó n sojú Bungudu/Maru ni ìpínlẹ̀ Zamfara , Abdul malik Zubairu ni ọjọbọ, ṣe ètò ìtọ́jú ọ̀fẹ́ fún àwọn ènìyàn ẹgbẹrun kan Àbọ̀,
O ní nitori àwọn tí kò ní anfààní láti ṣe ìtọjú ará wọn Látàrí wí pé ko sí ọwọ́ lọwọ…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Oyo Ti Awon Ilé Ìwòsàn Mẹ́fà Ti kò Dágájíá Tó
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Oyo ti pàṣẹ wí pé kí wọn ti àwọn ilé ìwòsàn méfà ti ko Dágájíá.
Nínú ọ̀rọ̀ àtẹ̀jade jáde láti ọwọ́ kọmísọ́nà fún ọ̀rọ̀ tó nlọ àti ìgbani lámọ̀ràn, ọmọba Dọtun Oyalade ni ọrọ náà ti di mímọ.
Ó ní àwọn ilé ìwòsàn méfà yìí…
Gómìnà ìpínlẹ̀ Yobe Fi Ọwọ́ Sí Kí Àwọn Ọdẹ Má Sọ Àwọn Ilé ìwòsàn ijoba Gbogbo Ni Ìpínlẹ̀ Naa.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Yobe, Mai Mala Buni tí fowo sí gbígbà awọn ọde tó le ni ẹgbẹrun kan láti má sọ àwọn ilé ìwòsàn ijoba to wa ni ìpínlẹ̀ náà
Dọ́kítà Babagana Tijjani to jẹ Akọ̀wé fún àwọn ilé ìwòsàn ijoba, gbe Òsùbà o Káre fún Gómìnà fún…