Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
Ẹ ríi dájú Pé, Ẹ̀ ń lọ Fún Àyẹ̀wò Ìlera Ní Gbogbo Ìgbà – Mallam Ali Muhammad Ali
Alàkóso ilé iṣé Awọn Oníròyìn fún Orílẹ̀-èdè (NAH) Mallam Ali Muhammad Ali ti rọ àwọn ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà láti má lo fún àyẹ̀wò ni gbogbo ìgbà ki wọn ba le mọ ipò tí ìlera wọn wa.
Ali ni àyẹwò ìgbà gbogbo gbọdọ jẹ ohun tí yóò mu wá…
Akọ́sẹ́mọsẹ́ Sọ Pé Àyẹ̀wò Àti Ìtọ́jú Àsìkò A Máa Lé Àrùn Jẹjẹrẹ Lọ
Onímọ̀ ìṣègùn òyìnbó, Oyesakin Adewumi ti sọ pé ayẹwo asiko ati rírí àrùn náà lásìkò a máa rán itọju ati ìdènà àrùn jẹjẹrẹ tó súyọ wá láti ìgbà èwe.
Dókítà Oyesakin sọ eyi nibi akanse irin ẹsẹ ti àrùn jẹjẹrẹ ti Akanimo Cancer…
Arábìnrin àkọ́kọ́ Anambra rọ àwọn obìnrin tó ń tọ́mọ lọ́wọ́ láti ṣe àfikún omi ọyàn tí…
Ìyàwó gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra, Ìyáàfin Nonye Soludo ti rọ àwọn obìnrin Nàìjíríà tó ń tọ́mọ lọ́wọ́ ni Anambra, láti ṣe àfikún omi ọyàn tí wọ́n ń fún àwọn ọmọ wọn ki omi máá baà le gbẹ lára wọn, nítorí bí ooru…
Ìgbóná-gbooru Kò Léwu Rárá Fún Àìsàn Ẹ̀jẹ̀ Rúru- Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́
Ọ̀jọ̀gbọ́n Augustine Odili, tí ó jẹ́ alága àjọ akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ nípa àìsàn ọkàn àti ẹ̀jẹ̀ rúru ni ó sàlàyé pé ìgbóná-gbooru tí ó ń wáyé ní àkókò yíì kò le è se àkóbá fún àwọn tí àìsàn ẹ̀jẹ̀ rúru ń bá…
Ìfikùn-lukùn Yóò Wáyé Lójúnà Àti Pẹ̀tù Sí Awuye-wuye Tí Ó Sẹlẹ̀ Látàrí Fífi Òfin…
Ẹka Ìjọba Àpapọ̀ tí ó wà fún ètò ìlera ti gbáradì láti wá ojútùú sí ìfẹ̀hónúhàn tí ó wáyé láti ọwọ́ àjọ FOBTOB látàrí fífi òfin de ìpèsè, mímu àti títa ọtí inú ọ̀rá, èyí tí ó wáyé ní…
Àìsàn Ibà Lassa Ti Tawé-Tagbò Ní Ìpínlẹ̀ Ebonyi, Ó Sekúpa Ènìyàn Mẹ́rìnlá
Gẹ́gẹ́ bí àtẹ̀jáde kan tí ẹka èto ìlera ìpínlẹ̀ Ebonyi se, àìsàn ibà Lassa ti sekúpa ènìyàn mẹ́rìnlá nínú àwọn mọ́kàndínlọ́gbọ̀n tí àìsàn náà ń bá á fínra, ní ìbamu sí ìfiléde tí ó wáyé ní ogúnjọ́…
Ààrùn Ibà Lassa gbẹ̀mí ènìyàn mẹ́rìnlá ní ìpínlẹ̀ Ebonyi
Ààrùn Ibà Lassa ti gbẹ̀mí ènìyàn mẹ́rìnlá nínú àwọn mọ́kàndín-lọ́gbọ̀n tí ó ti kó ààrùn náà bí àkọsílẹ̀ ní Ogúnjọ́, oṣù kejì, gẹ́gẹ́ bí ilé iṣẹ́ ìjọba àpapọ̀ tí ń mójútó ọ̀rọ̀ ìlera lápapọ̀, ti…
Àjẹjù Iyọ̀ Leè Mu Èmí Ènìyàn Kúrú:CSOs
Àjọ ìlera tó n mójú àgọ́ ará (NHED) pẹ̀lú ìbáṣepọ̀ àwọn ènìyàn láwùjọ sọ wí pé jíjẹ iyọ àjẹjù leè mú kí èmi ènìyàn kúrò sí igba tí yóò lo láyé .
Dọ́kítà Jerome Mafeni, NHED to je adari, àti abanidamoran fún iponlogo edi iyọ jije kun sọ…
Àìsàn Títa: Àjọ Àgbáyé fún Ètò Ìlera Ṣe Ìkìlọ Wí Pé Àìsàn Náà Yóò Pọ Diẹ Lọdun Yìí
Àjọ àgbáyé fún ètò ìlera (WHO) ni ọjọ́ ìṣẹgun pariwo wí pé àìsàn Títa yóò pọ diẹ nínú ọdún yìí.
Àjọ (WHO) wá gba àwọn ènìyàn lámọ̀ràn láti ní àkíyèsí ará púpọ, nitori o jẹ àìsàn to ma n ran, pàápàá jùlọ láàrin àwọn ọmọdé.
Wọn ni…
Àsìkò Oru: Ẹ má wọ Aṣọ Tí Kọ̀ Nipọn Lásìkò Yii o: Onímọ̀.
Adari àgbà fún ilé ìwòsàn Healing Hospital, Dọ́kítà Biodun Adewumi, ti pé àwọn ènìyàn láti rí wí aṣọ tó fẹlẹ ni wọn n wọ lásìkò oru yìí pàápàá jùlọ láàrin àwọn òṣìṣẹ́ eleto ìlera
Ó sọ èyí di mímọ nígbà tí ó n bá àwọn Oníròyìn sọ̀rọ̀ ni…