Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
NGO ní òun ti ní ipa lórí àwọn ènìyàn méjìlé-lọ́gbọ̀n Mílíọ́nù ní abala ìtọ́jú…
Ilé iṣẹ́ tí kìí ṣe tìjọba kan, Nigeria Solidarity Support Fund, NSSF, ti sọ pé òun ti ní ipa lórí àwọn ènìyàn méjìlé-lọ́gbọ̀n Mílíọ́nù ní ọdún mẹ́rin tí òun ti ń ṣiṣẹ́ ní abala ìtọ́jú ìlera lórílẹ̀-èdè.…
Àìsàn Lassa: Àjọ WAHO Tú Kun Ọjọ́ Gbígba Abéré Àjẹsára.
Àjọ ẹlẹ́tọ̀ ìlera ti wọn pẹ ni West Africa Health Organizations (WAHO) tí fi ọjọ́ kun gbígbà abẹrẹ ajẹsara nípa àìsàn Lassa fever kàkà kiri àgbáyé.
Ní ìlú Abuja ni ọ̀rọ̀ náà ti jáde ni ọjọ́rú láti ẹnu ọ̀gbẹni Alábá Balogun tó jẹ alukoro…
Ó Léwu Láti Ṣe Ìtójú Ará Yìí Ẹ Ló Sì Ilé ìwòsan Fún Ìtọ́jú Tó Péye: Àwọn Onímọ̀
Ààrẹ fún ìtọ́jú agbègbè àti ìlera àwọn ènìyàn Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (EPHPAN) Dọ́kita Samuel Akingbehin ti wọn jẹ onimọ ati olùtújù agbegbe ti ṣe ìkìlọ àti ewu tó wà nínú ki àwọn ènìyàn má ṣe ìtọjú ará wọn Lai gbà aṣẹ lọwọ Oníṣègùn òyìnbó.…
Ètò Ìlera Ọ̀fẹ́: Makinde Ṣíde Ìfilọ́lẹ̀ Ìlera Ọ̀fẹ́ Ní Ìjọba Ìbílẹ̀ Àríwá/Ìlà-Oòrùn Ìbàdàn.
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti jẹ ko di mímọ̀ pé ìṣèjọba òun yóò tẹ síwájú láti máa pèsè ètò ìlera lójúnà àti ri dájú pé ará ìlú wa ni ìlera pípé eléyìí tí yóò mú kí ọrọ̀ ajé rú gọ́gọ́ síi, ti ìṣẹ yóò sì dínkù ni àwùjọ.
Makibde…
Ilé ìwòsàn Ìkọ́ni pàtàkì ìwà láláàfíà àwọn òṣìṣẹ́ – CMD
Ọ̀gá Àgba Adarí Ìṣòògùn, CMD, ti gbọ̀ngàn ilé ìwòsàn Ìkọ́ni ti ilé Ẹ̀kọ́ Gí́ga Fáfítì Ọbafemi Awolọwọ , OAUTHC, Ilé-Ifẹ̀, Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun , Gúsù- Ilà Oòrùn, Nàìjíríà, Ọ̀jọ̀gbọ́n John Okeniyi ti ṣàlàyé pé…
Ìpínlẹ̀ Nasarawa: Àjọ NAFDAC Tí Ilé Iṣé Omi Ti Ko Péye Tó.
Àjọ tó n mójú tó ọrọ oúnjẹ àti ògùn ni Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NAFDAC ) tí gbèsè le ilé iṣé olómi kan ni ìpínlẹ̀ Nasarawa léyìn ìgbà ti wọn kófìrí wí pé wọn Oka ojú òṣùwọ̀n to.
Ọ̀gbẹni Anga Emmanuel to jẹ igbákejì àjọ NAFDAC ló sọ èyí di…
Orílè-èdè Sierra Leone Ṣe Ìkìlọ Nlá Fún ilẹ Áfíríkà Nípa Àìsàn Mpox.
Látàrí àìsàn tí wọn n pé Mpox Orílẹ-èdè Sierra Leone ti ké sita fún àwọn ènìyàn Orílẹ̀-èdè Áfíríkà láti ni akiyesi nlá nítorí àìsàn náà gbilẹ báyìí.
Wọn ní kí àjọ eleto ìlera ni akiyesi pàtàkì kí àìsàn náà wà ba gbilẹ sí.
Dọ́kítà…
Orílẹ̀-èdè Nàmíbíà Ri Àrídájú Àjàkálẹ̀ Àìsàn Ẹṣin Adúláwọ̀
Ẹ̀ka tó wà fún ìtọjú àwọn ẹranko orílẹ̀-èdè Nàmíbíà ti kéde àjàkálẹ̀ àìsàn ẹṣín ilẹ̀ Adúláwọ̀ - "African horse sickness", wọ́n sì ti kófí àìsàn nàá lára márùndínlọ́gbọ̀n ènìyàn níbi ẹ̀ka ti ń mójú tó àwọn ẹranko ní agbègbè Otjinene,…
Ènìyàn Ẹgbẹ̀rún Mẹ́rìndínlọ́gọ̀ta Ló Ti Lùgbàdí Àìsàn Ibà Láti Oṣù Kẹwàá Ní Orílẹ̀-èdè Nàmíbíà
Ènìyàn ẹgbẹ̀rún Mẹ́rìndínlọ́gọ̀ta tó lé ọgbọ̀nlélọ́gọ̀rún(56,130) ló ti lùgbàdí àìsàn ibà tí márùndínlọ́gbọ̀n ènìyàn sì ti kú láti ìgbà tí àìsàn nàá ti ń sọsẹ́ láti oṣù Kẹwa ọdún 2024, bí Mínísítà ètò ìlera Esperance Luvindao ṣe…
Ilé iṣé NNPC Foundation Ti Ṣe Ìrànlọ́wọ́ Iṣé Abẹ Ọfẹ Fún Àìsàn Ojú Ni Ìpínlẹ̀ Niger.
Ilé iṣé NNPC Foundation ti ṣe ètò ìtọ́jú iṣé abẹ ọfẹ fún àìsàn ojú fún àwọn ènìyàn Ẹ̀dẹ́gbẹ̀ta ni ìpínlẹ̀ Niger.
Iyaafin Emmanuela Arukwe tó jẹ adari àgbà pátápátá fún ilẹ Isé NNPC Foundation ló sọ èyí di mímọ̀ ni Minna ni ọjọ ẹti.…