Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ
This is a category for business news
Ìjọba Nàìjíríà Ṣé ìwé-ẹri Ìwé-àṣẹ Fún Àwọn Oníṣòwò Ajilẹ
Ìjọba Àpapọ̀, ní Ọjọ́bọ̀, ṣé agbekalẹ àwọn iwe-ẹri àti iyọnda títà àti rírà ajilẹ ní ilẹ̀ Nàìjíríà.
Èyí wà nínú ọrọ kàn tí Iyaafin Modupe Olatunji, tí Federal Ministry of Agriculture and Rural development ni Abùjá
Akọ̀wé àgbà,…
Àtúntò Ètò Ọrọ̀ Ajé Nàìjíríà Ti Bẹ̀rẹ̀ Ní Pẹrẹwu
Ààrẹ Muhammadu Buhari ti yan àwọn alákoso titun fún àtuhntò ọrọ̀ ajé. Ó sọ pé, pèlú àìrajaja tí ó ń bá ètò ọrọ̀ ajé f́inra ní àgbáyé, ọrọ̀ ajé Nàìjíríà sì ń gbèrú síi.
Nígbal tí…
Ilé Isẹ́ tí ó ń Mójútó Ìdókoòwò gba Àmìn Ẹ̀yẹ
ẸKa tí ó ń mójútó ètò ìfowópamọ́ àti ìdókoòwò NDIC ti gba àmìn ẹ̀yẹ ìjọba àpapọ̀ fún ìfakọyọ lẹ́nu isẹ́ àti síse àmójútó owó tí ó kó ẹsẹ járí.
Akòwé àgbà ìjoba àpapọ̀, nígbà tí ó ń…
Àwọn ọkọ̀ òfurufú Òkèèrè Gbọ́dọ̀ Ta Tìkẹ́ẹ́tì wọn Ní Náírà – Mínísítà ọkọ̀…
Mínísítà fún Ọkọ̀ òfurufú Nàìjíríà, Hadi Sirika sọ pé àwọn ọkọ̀ òfurufú òkèèrè gbọ́dọ̀ ta àwọn tíkẹ́ẹ́tì wọn ní Náírà,ó sọ pé ìjọba pinnu láti fimú ẹni tó bá lu òfin yìí dánrin, tí ó sì tẹnumọ́ pé…
Ẹ máá fi Ẹ̀tọ́ àwọn òṣìṣẹ́ tó ti jẹ́pè ọlọ́run dùn wọ́n o
Ọ̀gá àgbà fún àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba àpapọ̀,HOS, Dókítà Fọláṣadé Yẹmí-Ẹ̀san, ti fi ẹ̀dùn ọkàn rẹ̀ hàn lórí ìwà àìṣedéédé àwọn ilé-iṣẹ́ dójútòfò lórí àìsanwó àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba tó ti jẹ́pè ọlọ́run.…
Àyíká Ìṣòwò: Igbákejì ààrẹ Ọ̀sínbàjò rọ àwọn ìjọba ìpínlẹ̀ láti ríi dájú pé…
Igbákejí Ààrẹ orílẹ̀-eldè Nàìjíríà, Ọ̀jọ̀gbọ́n Yẹmí Ọ̀ṣínbàjò sọ pé àwọn ìjọba ìpínlẹ̀ àti àwọn ilé-iṣẹ́ wọn ní ipa pàtàkì láti kó láti ríi dájú pé wọ́n pèsè àyíká tó lálààfíà fún ìṣòwò láti…
Ilé-iṣẹ́ ẹ̀rọ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ káríayé pinnu láti ṣòkòwò Ní Nàìjíríà
Ní àtẹ̀lé ìgbékàlé àwọn agbára ọjà Nàìjíríà, olùdókòwò ẹ̀rọ ìbáraẹnisọ̀rọ̀ káríáyé, Ẹgbẹ́ Ọ́réńgì, ti pinnu láti gbé ìgbésẹ̀ pàtàkì tí ó ga jùlọ ní Áfíríkà, ní àwọn agbègbè onírúurú, pẹ̀lú…
Títúnyàn: Ààrẹ Bùhárí kí Alága Ẹgbẹ́ BUA kú oríire
Ààrẹ Mùhámmádù Bùhárí ti kí Abdul Samad Rabiu, Alaga ẹgbẹ́ BUA, lórí bí Ààrẹ Faranse, Emmanuel Macron ṣe tún yàn án padà gẹ́gẹ́ bí Ààrẹ ìgbìmọ̀ oníṣòwò ilẹ̀ Faransé àti Nàìjíríà.
Ààrẹ gbóríyìn fún Rabiu fún ipa pàtàkì tó kó…
Ilé-iṣẹ́ Súgà Dangote yóò bẹ̀rẹ̀ ìṣelọ́pọ̀ ní Ìpínlẹ̀ Násáráwá
Gómìnà ìpínlẹ̀ Násáráwá, ariwá ààrin ìlú Nàìjíríà, Gómìnà Abdullahi Sule, ti sọ pé ilé-iṣẹ́ Súg̀a Dangote yóò bẹ̀rẹ̀ ìṣelọ́pọ̀ láìpẹ́ ní ìpínlẹ̀ náà.
Gomina Sule soro yii lasiko ti o n gbalejo awọn ọmọ…
Ilé-ẹ̀kọ́ gíga fún àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n oníṣirò ICAN, ṣe ìlérí láti túnbọ̀ gbéṣẹ́ rẹ̀ lárugẹ
Ilé-èkọ́ gíga fún àwọn ọ̀jọ̀gbọ́n oníṣirò ní ìlú Awka, gúúsù ilà-oòrùn Nàìjíríà, ti ṣe ìlérí láti tọ́ àwọn ọmọ ẹgbẹ́ rẹ̀ sọ́nà láti jẹ́ alámọ̀dájú irú ẹ̀ lágbáàyé, tí ó sì sọ pé ilé-ẹ̀kọ́ náà jẹ́…