Browsing Category
ÌRÒYÌN ILẸ̀ ÀFÍRÍKÀ
This is a category for Africa news
Alákatakítí Mọ́kànlélógún Pàdánù Ẹ̀mí Ní Sebabougou
Àjọ Omọ Ogun Orílẹ̀-èdè Mali ti fi ọ̀rọ̀ léde pé, àjọ náà ti rán àwọn alákatakítí mọ́kànlélógún lọ sí ọ̀run àpàpàndodo, nígbà tí ikọ̀ ọmọ ogun se ìkọlù sí ibùba wọn tí ó wà ní Sebabougou, Orílẹ̀-èdè Mali…
Tani Yóò Jáwé Olúborí Láàrín Al Ahly Àti Sundowns Nínú Ìdíje CAF
Al Ahly àti Mamelodi Sundowns tí ṣetán ìfẹ́sẹ́wọsẹ́ kán ní alẹ́ ọjọ́ Ẹtì ní pápá ìṣèré 'Cairo International' bí wọ́n tí n ja fún ayé níbi ìparí eré-ìdárayá tí 'CAF Champions League.'
Ìfẹ́sẹ́wọsẹ́ àkọkọ́ ní 'Pretoria' parí ní ọ̀mì,…
Mínísítà Gbóríyìn Fún Àwọn Ẹṣọ Ghana Kán Fún Ìgbàlà Àwọn Ọmọ Nàìjíríà Ogún-lugba-Dín-Kán
Mínísítà fún Ìpínlẹ̀ fún ètò Ọrọ òkèèrè, Bianca Odumegwu-Ojukwu, tí gbóríyìn fún àwọn aláṣẹ orílẹ-èdè Ghana fún Ìgbàlà àwọn ọdọ Nàìjíríà Ogún-lugba-Dín-Kán (219) tí wọ́n gbé lọsí orílẹ-èdè Ìwọ̀-oòrùn Áfíríkà náà tí wọ́n sí fí ipá mú wọ́n…
Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Ghana Dá Adájọ́ Àgbà Dúró Lẹ́nu Iṣẹ́
Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Ghana, John Mahama ti dá àdájọ́ àgbà, Gertrude Torkornoo dúró lẹ́nu iṣẹ́ fún àkókò díẹ̀ tí wọn yóò fi se ìwádìí àwọn ẹ̀sùn tí wọ́n fi kàn-án
Èyí ni ó jẹ́ ìgbà àkọ́kọ́ ti wọn…
Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Kenya Gúnlẹ̀ Sí China
Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Kenya William Ruto ti gúnlẹ̀ sí ìlú Beijing ní alẹ́ ọjọ́ Ìsẹ́gun fún àbẹ̀wò lẹ́nu iṣẹ́ ọlọ́jọ́ mẹ́rin sí Orílẹ̀-èdè China
Àbẹ̀wò náà ni ó jẹ́ ẹlẹ́ẹ̀kẹta irú rẹ̀ sí China nígbà tí ó ti gun…
Aṣojú Ethiopia kéde èròńgbà orílẹ̀-èdè láti darapọ̀ mọ́ NDB
Aṣojú Ethiopia si Brazil, Leulseged Tadese Abebe, ti sọ pé kí orílẹ̀-èdè òun jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ilé ìfowópamọ́ ìdàgbàsókè tuntun BRICS jẹ́ ọ̀kan lára ohun tó wà lọ́kàn òun fún ọdún tí a wà yìí.
Abebe ṣalaye ninu…
Ilé iṣẹ́ tí ń mójútó Ìrìn àjo lọsí orílẹ̀-èdè mìíràn dá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè…
Ilé iṣẹ́ tí ń mójútó Ìrìn àjo lọsí orílẹ̀-èdè mìíràn ní Nàìjíríà (NIS), Aala Agbofinro Illela ti ipinlẹ Sokoto, ti fidiẹ mulẹ pe wọn ti dá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Mali méjìlé-lọ́gọ́ta padà lati oju ile Illela.…
Ẹgbẹ Alátakò pàtàkì Tanzania kò ní ẹ̀tọ́ sí Ìdìbò
Ẹgbẹ Alátakò pàtàkì Tanzania, CHADEMA, kò ní ní àǹfààní láti kópa nínú ìdìbò gbogbogbòò tó ń bọ́ lọ́nà, àgbà òṣìṣẹ́ ìgbìmọ̀ olómìnira tí ń mójútó ètò ìdìbò lórílẹ̀-èdè ló kéde rẹ̀ lọ́jọ́…
Ọ̀pọ̀ Èwe Dojúkọ Ìpáǹle Ìbánisùn Ní Àríwá Congo- UNICEF
Bí àjọ UN ṣe sọ, àwọn ọdọmọde, ewé ti wọn kò ìdá kan o lé nínú ẹgbẹrun mẹwa ẹ̀sùn ìbánilòpọ̀ àwọn ọmọdé ni wọn n ṣe tìpá tì ìkúkùù ìbálòpọ̀ fún ní ìlà oòrùn orílẹ̀-èdè Congo ni ìbẹrẹ oṣù méjì ọdún yìí.
Bí agbẹnusọ àjọ UNICEF, James Elder…
Àgbáríjọpọ̀ Ọmọ Nàìjíríà Ní Orílẹ̀-èdè South Africa Yan Olóyè Tuntun
Àjọ Nigerian Union South Africa (NUSA) yoo yan adari àti olóye apapọ ọmọ ẹgbẹ́ tuntun ní ọjọ́ Eti
Akọsilẹ ti àjọ àgbà orilẹ ede yìí fi síta fún ọmọ Naijiria ní orile-ede South Africa sọ pe akori ètò náà yóò jẹ '' Wiwa ní isokan ọmọ…