Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN ILẸ̀ ÀFÍRÍKÀ

This is a category for Africa news

Mínísítà Gbóríyìn Fún Àwọn Ẹṣọ Ghana Kán Fún Ìgbàlà Àwọn Ọmọ Nàìjíríà Ogún-lugba-Dín-Kán

Mínísítà fún Ìpínlẹ̀ fún ètò Ọrọ òkèèrè, Bianca Odumegwu-Ojukwu, tí gbóríyìn fún àwọn aláṣẹ orílẹ-èdè Ghana fún Ìgbàlà àwọn ọdọ Nàìjíríà Ogún-lugba-Dín-Kán (219) tí wọ́n gbé lọsí orílẹ-èdè Ìwọ̀-oòrùn Áfíríkà náà tí wọ́n sí fí ipá mú wọ́n…

Ilé iṣẹ́ tí ń mójútó Ìrìn àjo lọsí orílẹ̀-èdè mìíràn dá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè…

Ilé iṣẹ́ tí ń mójútó Ìrìn àjo lọsí orílẹ̀-èdè mìíràn ní Nàìjíríà (NIS), Aala Agbofinro Illela ti ipinlẹ Sokoto, ti fidiẹ mulẹ pe wọn ti dá àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Mali méjìlé-lọ́gọ́ta padà lati oju ile Illela.…
button