Browsing Category
ÌRÒYÌN ILẸ̀ ÀFÍRÍKÀ
This is a category for Africa news
Ilé Ẹjọ́ Kenya Bù Owó Ìtanràn Fún Àwọn Ajíkòkòro Lọ Sí Ìlú Ibòmíràn
Ilé ẹjọ́ orilẹ̀-ède Kenya ti ju àwọn ọkùnrin mẹrin kan sì ẹ̀wọ̀n ọdún kan tàbí kì wọ́n san owó ìtanràn tó le ní Ẹgbẹ̀rún méje Dọ́là - $7,700 (£5,800) ní igbiyanju wọn láti jí ààyè ayaba àwọn kòkòrò jáde kúrò ní orílẹ̀-èdè náà.…
Orílè-èdè Congo Àti Ruwaba Buwọ́lù Ìwé Àlàáfíà.
Nípa ètò àlàáfíà ti Orílẹ-èdè U.S n gbìyànjú láàrin Orílè-èdè Congo àti Rwanda, àwọn Orílẹ̀-èdè méjèjì ti buwolu ìwé àlàáfíà láàrin ara wọn.
Ààrẹ Donald Trump to jẹ Ààrẹ Orílẹ̀-èdè U.S , to sí jé Olùdámọ̀ràn pàtàkì fún ilẹ Áfíríkà àti…
Fásítì Cairo Ni Ó Peregedé jùlọ Nípa Imo Ogún Ni Ilé Áfíríkà.
Níbi ikẹkọ nípa ètò ẹ̀kọ́ nípa ogún ni Fásítì Cairo, wọn ní Fásítì yìí lo Peregede jùlọ ni ilé Egypt àti kàkàkí Áfíríkà.
Gẹ́gẹ́ bí ìròyìn ti sọ, wọn ní Fásítì Cairo ló gbé igbá oróke nípa ètò ògún àti àwọn ibi méwàá miran.
Wọn láàrin…
RSF Ṣé Ìfilọ́lẹ̀ Ìkọlù Dúróònù Àkọ́kọ́ Lórí Pápákọ́ Òfurufú Sudan
Àwọn ajá-gbára (Rapid Support Forces RSF) tí Sudan tí ṣé ìfilọ́lẹ̀ àkọ́kọ́ kán lórí pápákọ́ òfurufú àwọn Ológun àti àwọn òun meré-meré àgbègbè Pápákọ́ Òfurufú Sudan náà.
Ìgbà àkọ́kọ́ rè tí wọ́n yóò ṣé irúfẹ́ ikọlù náà sì Pápákọ́…
Ìgbákejì Ààrẹ Zimbabwe Ṣé Ìpàdé Pẹ̀lú Mínísítà Ilẹ̀ Òkèèrè Tí Vatican
Ìgbákejì Ààrẹ Zimbabwe, Constantino Chiwenga, ṣé ìpàdé pẹ̀lú Mínísítà ile òkèèrè tí Vatican, Archbishop Paul Richard Gallagher, ní Rome ní Ọjọ́ Àbámẹ́ta.
Ìpàdé náà dá lórí àwọn ìpèníjà ìṣèlú àti ètò ọrọ-àjé tí Zimbabwe, pẹ̀lú àwọn…
Orílẹ̀-èdè Nàmíbíà Ri Àrídájú Àjàkálẹ̀ Àìsàn Ẹṣin Adúláwọ̀
Ẹ̀ka tó wà fún ìtọjú àwọn ẹranko orílẹ̀-èdè Nàmíbíà ti kéde àjàkálẹ̀ àìsàn ẹṣín ilẹ̀ Adúláwọ̀ - "African horse sickness", wọ́n sì ti kófí àìsàn nàá lára márùndínlọ́gbọ̀n ènìyàn níbi ẹ̀ka ti ń mójú tó àwọn ẹranko ní agbègbè Otjinene,…
Ìjà Ìgboro Agbègbè Sọ Mẹ́ẹ̀dógún Ènìyàn Dolóògbé, Mẹ́rìndínlógún Farapa Ní Gúsù Sudan
Ó kéré tán ènìyàn mẹ́ẹ̀dógún ti dágbére f'áyé tí mérìndínlógún míràn sì tún farapa nínú àwọn ikọ̀lù ìjà Ìgboro agbègbè ní Tonj South County, Warrap State, Ariwa South Sudan, ẹnìkan sọ èyí ní ọjó Ẹtì.
Kọmísọ́nà Tonj South County, Ring…
Ènìyàn Ẹgbẹ̀rún Mẹ́rìndínlọ́gọ̀ta Ló Ti Lùgbàdí Àìsàn Ibà Láti Oṣù Kẹwàá Ní Orílẹ̀-èdè Nàmíbíà
Ènìyàn ẹgbẹ̀rún Mẹ́rìndínlọ́gọ̀ta tó lé ọgbọ̀nlélọ́gọ̀rún(56,130) ló ti lùgbàdí àìsàn ibà tí márùndínlọ́gbọ̀n ènìyàn sì ti kú láti ìgbà tí àìsàn nàá ti ń sọsẹ́ láti oṣù Kẹwa ọdún 2024, bí Mínísítà ètò ìlera Esperance Luvindao ṣe…
Àwọn Àrin rìn Mẹfa Ló Jade láyé Ní Agbègbè Libyan.
Ó kéré ju àwọn àrin rìn àjò méfà ni o jáde láyé ní agbègbè Libyan Misrata.
Gẹgẹ bí ẹní ti ìròyìn náà soju rẹ, wọn ni àwọn ìjàmbá tó n ma wáyé ni èyí látàrí bi àwọn àrin rìn àjò ba fẹ ló sì Orílè-èdè Europe nígbà tí wọn bá gbà láti làá…
Ẹgbẹ́ Àwọn Ọdọ Olùwẹ̀ Ọmọ Nàìjíríà Dé Sí Egypt Fún Ìdíje
Ẹgbẹ́ ọdọ Nàìjíríà tí dé sí Orílẹ̀-èdè Egypt fún ìdíje ọdọ ilẹ̀ Áfíríkà ní Egypt tí a ṣètò fún ọjọ́ kọkandinlọgbọn oṣù kẹ́rin sí ọjọ́ kẹ́ta oṣù karùn-ún ọdún 2025.
Ẹgbẹ́ náà tó ní àwọn olùwẹ̀ mẹ́rinlá (14), àwọn ọmọkùnrin mẹjọ (8)…