Browsing Category
ÌRÒYÌN ILẸ̀ ÀFÍRÍKÀ
This is a category for Africa news
Àṣá Ti Fò, Ojú Ti Bafana Bafana Padà Lọ Sí Ilé Wọn.
Ìbẹ̀rẹ̀ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ yìí o dẹrùn rárá láàrín Ikọ Super Eagles Ati Ikọ Bafana Bafana, Imura eré laá ò fi ọmọ ayò ṣe ni South Africa gbe wa si ori pápá, wọ́n mi ọkan àwọn super eages ni abala akọkọ ìfẹsẹ̀wọnsẹ̀ náà, wọn kọrin ọkan yin o ni…
Gbọ́misiomiòtó Ló Ń Ṣẹlẹ Bayii Ni Orílẹ̀-èdè Senegal Báyìí Látàrí Bí Wọ́n Ṣe Sún Ètò Ìdìbò Síwájú
Látàrí bi wọ́n ṣe sún eto Ìdìbò Síwájú ni Orílẹ̀-èdè Senegal àwọn ará ìlú n ṣe ìwọ́de èyí tó mú wọn kọlù àwọn ọlọ́pàá ni iwájú ita ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin.
Ìròyìn fi to wa létí wí pé wọn kọ̀wé láti fi kún àkókò Ààrẹ to wà lórí ipo báyìí Macky…
Orílẹ̀-èdè Burkina Faso Di Orílẹ̀-èdè Áfíríkà Kejì Ti Ó Fàyè Gbà Ògùn Abẹrẹ Ajẹsara Ti Àisìán Ibà…
Láìpẹ́ yìí ni Orílẹ̀-èdè Burkina Faso di Orílẹ̀-èdè Áfíríkà Kejì tí o pàṣẹ pé kí wọn mú ògùn àisìán iba abẹrẹ ajẹsara wọ ètò abẹrẹ ajẹsara fún àwọn ọmọ wẹ́wẹ́.
Orílẹ̀-èdè náà ti Kéde ògùn àisìán iba náà ti wọn pè RTS,S, sí àwọn àgbègbè…
Àjọ ECOWAS Ti Ké Sí Orílẹ̀-èdè Senegal Láti Mú Ọjọ́ Mìíràn Fún Ìdìbò Ààrẹ Tí Wọ́n…
Àjọ tó ń rísí ọrọ̀ ajé àwọn ipinlẹ Iwọ-oorun Afirika (ECOWAS) ti rọ àwọn alaṣẹ Orílẹ̀-èdè Senegal lati jára mọ mímú ọjọ tun tun fún idibo aarẹ Orílẹ̀-èdè náà tí wọn sun síwájú
Agbegbe tó sọrọ yii ninu ọrọ kan ti…
Ààrẹ Senegal Sùn Ọjọ́ Ìdìbò Síwájú Látári Wàhálà Àwọn Olóṣèlú
Ààrẹ Senegal Macky Sall tí sùn ọjọ́ ìdìbò èyí tó yẹ́ kó wáyé nínú Oṣù yí síwájú látári ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹsùn idíwọ́ àwọn olùdíje láti máa kópa.
Ààrẹ náà tó tún sọ pé òun kìí yóò díje dúpo lẹyìn sáà Kéjì oún ṣùgbọ́n kó kéde ọjọ́ títún mìíràn…
Hage Geingob: Ààrẹ Namibia kú ní ẹní ọdún méjìlèlọgọ́rin
Ààrẹ Namibia, Hage Geingob, kú ní ẹní ọdún méjìlèlọgọ́rin (82) níbí tó tí ń gbá ìtọjú ní Ilè-ìwòsàn kàn ní Olú-ìlú Orílẹ̀-èdè náà, Windhoek.
Ìgbákejì Ààrẹ Namibia Nangolo Mbumba ló kéde ikú Ọ̀gbẹ́ni Geingob ní kùtùkùtù ọjọ́ Àìkú, tí…
Àṣá Gbé Ẹtu Mì Lá wọlé Sùn Lọ́jọ́ Ẹtì Ní Orílẹ̀-èdè Côte d’Ivoire.
Ẹgbẹ agbabọọlu super eagles bẹrẹ ifigagbaga oun pẹlu orilẹ-ede Angolla ti a mọ si Black Sable antelopes pẹlu idaniloju to dantọ ni dede aago mẹfa aabọ, ọjọ ẹtì.
Ẹgbẹ agbabọọlu Angolla naa o dẹrùn rara, bi wọn ṣe n sa si bi ni wọn n sa…
Ìdí Tí A Fi Kúrò Nínú Àjọ ECOWAS- Ìjọba Burkina Faso Fi Ohùn Akin Sọ̀rọ̀
Ìkédé Orílẹ̀-èdè Burkina Faso, Mali ati Niger láti kúrò nínú àjọ ECOWAS ni ó ti ń mú ọ̀pọ̀lọpọ̀ awuye-wuye jáde
Adarí ìjọba Orílẹ̀-èdè Burkina Faso ni ó sọ ìdí tí ìgbésẹ̀ náà fi wáyé ní ìlú…
Ìsẹ̀lẹ̀ Iná Ńlá Wáyé Ní Nairobi Nígbà Tí Afẹ́fẹ́ Gáàsì Gbiná
Afẹ́fẹ́ gáàsì bù yàrì tí iná ńlá sì sẹ́yọ ní Nairobi, olú ìlú Orílẹ̀-èdè Kenya níbi tí ènìyàn méjì ti pàdánù ẹ̀mí tí okòó-lé-lúgba àti méjì sì fi arapa yán-na-yàn-na
Ọkọ̀ tí ó ń gbé…
Olórí Ẹgbẹ́ Alátakò Zimbabwe Yóò Gbá Ìtusílẹ̀ Láìpẹ́
Olórí ẹgbẹ́ alátakò ìjọba tí Orílẹ̀-èdè Zimbabwe, Job Sikhala, yóò gbá òmìnira láìpẹ́.
Ilé-ẹjọ́ kàn ní ọjọ́ Ìṣẹgun, ọ̀gbọ̀n ọjọ́, Oṣù Kínní. Olóṣèlú náà wà ní àtimọ́le ní Oṣù Karùn-ún ọdún 2022 lẹyìn tó gbá àwọn aráàlú níyànjú látí…