Browsing Category
ÌRÒYÌN ILẸ̀ ÀFÍRÍKÀ
This is a category for Africa news
Alága ECOWAS pè fún ìṣọ̀kan ní iwọ̀ oòrùn Áfíríkà
Alága ọrọ̀ ajé Agbègbè àwọn orílẹ̀ èdè iwọ̀ oòrùn Adúláwọ̀ (ECOWAS), tí ó tún jẹ́ ààrẹ Nàìjíríà Bọla Ahmed Tinubu ti pé fún ìṣọ̀kan ní ẹkùn, tí ó sì wí pé àríyànjiyàn lórí ìgbàjọba lọ́nà tí kò…
Ilé ìfowópamọ́ àpapọ̀ fún Áfíríkà yóò bẹ̀rẹ̀ ní 2028
Ààrẹ Nàìjíríà Bọla Ahmed Tinubu ti sọ pé ìjọba òun yóò jẹ́ kí ìgbìmọ̀ Ẹgbẹ́ Àdúláwọ̀ ní àjọṣepọ̀ pẹ̀lú àwọn orílẹ̀-èdè ẹgbẹ́ láti ri pé Ilé ìfowópamọ́ àpapọ̀ fún Adúláwọ̀ bẹ̀rẹ̀ ní 2028, bí wọ́n ti ṣètò…
Wọ́n Yan Obìnrin Sí Ipò Mínísítà Ètò Ààbò Fún Ìgbà Àkọ́kọ́ Ní Liberia
Ààrẹ orílẹ̀-èdè Liberia, Joseph Boakai ti yan ogagun obinrin, Geraldine George to ti feyinti sí ipò adele Mínísítà ètò ààbò leyin ti ìyàwó awọn ologun se iwode lati takò ẹni to wa ní ipò náà tẹ́lẹ̀.
Obìnrin náà dara pọ̀ mö awọn…
South Africa Ṣetán Láti Rán Ọmọ Ogun Tó Dín Díẹ̀ Ní Ẹgbẹ̀rún Mẹ́ta Lọ Sí Ìlà Oòrùn DRC
South Africa ti ṣetán láti ran ọmọ ogun Ẹgbẹrun mẹta o din ni ọgọrùn lọ sí Democratic Republic of Congo, DRC lati koju ikọ̀ ọmọ ogun ọlọ̀tẹ̀ ni ìlà oòrùn.
Ninu akosile, ààrẹ South Africa, Cyril Ramaphosa sọ pé bi won se n ran…
Orílẹ̀-èdè Kenya: Arákùnrin Eléré Sísá Fàágù Ti Àgbáyé Nì Jayé Láyè Nípasẹ̀ Ìjàmbá Ọkọ́.
Arakunrin to di ìlú mọọkà nipasẹ eré ṣiṣan oni fàágù Kenya Kelvin Kiptum, ẹni ọdún merinlelogun jayé láyé Látàrí ìjàmbá ọkọ̀ ni Orílẹ̀-èdè rẹ.
Òun àti Olùkọ rẹ Rwanda Gervais Hakizimana ni wọn padanu èmí wọn ni ọjọ́ àìkú Látàrí ìjàmbá…
Ẹgbẹ́ olóṣèlú Míràn Ti Orílẹ̀-èdè Ghana Tako Sísùn Ìdìbò Síwájú.
John Mahama, to jẹ adari ẹgbẹ́ olóṣèlú National Democratic Congress, so wí pé Sísùn Ìdìbò Síwájú ko le ṣẹ e ṣe
Èyí di mímọ nígbà tí wọn n fi ọ̀rọ̀ wa lẹnu wò ni Accra.
Wọn ni ki won sún eto idibo siwaju sí ìparí ọdún yìí, ṣugbọn àwọn…
Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà Pè Fún Ìwádìí Tí Ó Gbépọn Látàrí Ẹ̀sùn Ìsekúpani Tí Ó…
Orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà ti pè fún ìwádìí látàrí ẹ̀sùn ìpànìyàn tí ó wáyé ní àgbègbè Amhara, Ethiopia níbi tí wàhálà nla ti bẹ́ sílẹ̀ láàrin àwọn ọmọ ológun àti àwọn ará ìlu níbi tí ọgọ́rin ènìyàn ti…
Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Liberia Se Ìfilọ́lẹ̀ Ìgbógun Ti Ìwà Síse Owó Ìlú Kúmọ-kùmọ
Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Liberia, Joseph Boakai ti gbé ìgbésẹ̀ akin láti gbógunti ìwà àjẹbánu nígbà tí ó se àgbékalẹ̀ ètò ìwádìí fún ẹka ìjọba mẹ́ta tí ó se pàtàkì, tí Báńkì àpapọ̀ náà sì wà lára wọn…
Ààrẹ Liberia Ṣé Àyẹ̀wò Oògùn Tí Kó Tọ́ Nínú Àrà
Ààrẹ Liberia Joseph Boakai tí ṣé àyẹ̀wò fún àwọn òògùn àtí àwọn nkán tí kò tọ́ nínú àrà.
Olórí orílẹ̀-èdè Liberia ní ọjọ́ Ọjọ́rú ṣé àyẹ̀wò àwọn òògùn kàn èyí tí o tí ṣé ìlérí látí ṣé làkókò ibanisọrọ rẹ̀ sí Ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin ní ọjọ́…
Amẹ́ríkà, Elétò Ààbò Orílẹ̀-èdè Kenya Sọ Pàtàkì Ìwúlò Ààbò Àjọṣepọ̀
Akọwe ètò ààbò ti orile-ede Amerika, Lloyd Austin ti sọ pataki ìwúlò ààbò àjọṣepọ̀ Amerika àti Kenya bi ó se se ìpàdé pọ̀ pẹ̀lú, Aden Bare Duale ti ilẹ̀ Kenya ní Pentagon.
Lẹ́yìn ìpàdé, wọn tọwọ́ bọ ìwé adehun olodun marun…