Browsing Category
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
This is a category for politics news
Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Ìpínlẹ Nasarawa Pín Ẹ̀bùn Ọdún Kérésì Fún Àwọn Opó,…
Adarí Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin ìpínlẹ Nasarawa, Ọnọrébù Danladi Jatau ti pín àpò ìresì irinwó, àti owó fún àwọn ọ̀ọ́dúnrún aláìní àti opó ní ẹkùn tí ó ń sojú fún ní ìpínlẹ̀ Nasarawa
Jatau sọ pé…
Ọmọ Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Pín Ẹ̀bùn Owó, Asọ Àti Àwọn Ohun Èlò Míràn Ní Ìpínlẹ̀ Ebonyi
Ọmọ Asòfin tí ó ń sojú ẹkùn Ebonyi/Ohaukwu ní Ilé Asòfin Abuja, Pastor Eze Nwachukwu Eze ti fi àpò ìresì, Asọ, Ajílẹ̀ ta àwọn ènìyàn rẹ̀ lọ́rẹ láti se ìrànlọ́wọ́ fún wọn síwájú ọdún kérésìmesì àti ọdún tuntun…
Adarí ilé kéde pé ipò Umahi, Giadam ṣófo
Adarí ilé ìgbìmọ̀ Nàìjíríà, Godswill Akpabio ti kéde pé ipò àwọn Sẹ́nétọ̀ méjì, David Umahi (Gúsù Ebonyi) àti Ibrahim Giadam (ilà oòrùn Yobe ) ti ṣófo, nígbà tí wọ́n ti yàn wọ́n bí mínísítà.
Sẹnetor…
Mínísítà fún Iṣẹ́ nígbà kan rí, Lalong di Sẹ́nétọ̀
Wọ́n ti búra fún mínísítà Nàìjíríà fún iṣẹ́ àti ìgbànisíṣẹ́ tẹ́lẹ̀ rí, Ọ̀gbẹ́ni Simon Lalong tí ń ṣojú Gúsù Plateau, Gúsù ìjọba àpapọ̀ ní ilé ìgbìmọ̀ ẹlẹ́ẹ̀kẹwàá.
Adari ile igbimọ, Godswill Akpabio ni o ṣe…
APC ń ṣapá rẹ̀ láti pèsè ìgbé ayé ìrọ̀rùn fún àwọn ọmọ Nàìjíríà -Ganduje
Alága àpapọ̀ ti ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress, APC, Dókítà Abdullahi Ganduje ti sọ pé ẹgbẹ́ náà ń ṣiṣẹ́ papọ̀ pẹ̀lú ìjọba láti ri pé àwọn ọmọ Nàìjíríà gbé ìgbé ayé ìrọ̀rùn .
Ganduje sọ eyi nibi…
PDP pe àwọn aṣòfin tó fi ẹgbẹ́ sílẹ̀ lọ sí òmíràn ní Rivers láti fi ipò sílẹ̀
Ẹgbẹ́ alátakò Nàìjíríà, the Peoples Democratic Party, PDP, ti dúró lórí pé àwọn ọmọ ẹgbẹ́ ilé ìgbìmọ̀ ìpínlẹ̀ Rivers mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n tó ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ All Progressives Congress, APC gbọ́dọ̀ fi ipò wọn sílẹ̀.
Ẹni…
Àwọn tó nííṣe ní Nasarawa gbóríyìn fún ìgbésẹ̀ ìdàgbàsókè Sule
Alága àpapọ̀ fún ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress (APC), tẹ́lẹ̀ rí Sẹnetor Abdullahi Adumu, àti àwọn tó nííṣe ti gbóríyìn fún ìgbésẹ̀ ìdàgbàsókè ìpínlẹ̀ Nasarawa, ti Gómìnà Abdullahi Sule ní ọdún mẹ́rin…
Awuye-wuye Ìpínlẹ̀ Rivers Ń Tẹ̀síwájú Èyí Tí Ó Mú Kí Àwọn Kọmísọ́nà Kọ̀wé Fipò…
Kọmísọ́nà Fún Ètò Ẹ̀kọ́ ní Ìpínlẹ̀ Rivers, Ọ̀jọ̀gbọ́n Prince Mmom ti darapọ̀ mọ́ àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ méjì tí wọ́n kọ̀wé fipò sílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Rivers
Mmom síṣọ lójú ọ̀rọ̀ náà pẹ̀lú ìwé tí ó kọ ráńsẹ́ sí…
Ilé Ìgbìmọ̀ Asòfin Pàrọwà Sí Àjọ Ọlọ́pàá Láti Mú Ìdàgbàsókè Bá Ètò Àbò
Ìgbìmọ̀ Ilé Asòfin lóri ọ̀rọ̀ Ọlọ́pàá ti rọ Mínísítà Fún Ọ̀rọ̀ Ọlọ́pàá àti ọ̀gá àgbà àpapọ̀ Àjọ Ọlọ́pàá láti gbé ìgbésẹ̀ tí ó yẹ láti ríi dájú pé ètò àbò tí ó péye wà jákè-jádò Orílẹ̀-èdè…
Adari ilé ìgbìmọ̀ Abbas Ki Wike Ku Órire Ayẹyẹ Ọjọ Ibi Re Ni Ẹni Mẹ́rìndínlọ́gọ́ta.
Adari ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Abbas Tajudeen ti ba ọlọ́jọ́ìbí Nyesom Wike yajo ọjọ́ ìbí re ni ẹni Mẹ́rìndínlọ́ọ̀gọ́ta loke ìpẹ̀.
Abbas ṣe àpèjúwe rẹ gẹ́gẹ́ bí ẹni tí o ṣe fi okan tan nipa iṣẹ rẹ sí Orílẹ̀-èdè Nàìjíría.
Olubadamoran pataki…