Browsing Category
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
This is a category for politics news
Ìbò àdìkù: Ilé ìgb̀imọ̀ Zamfara búra fún aṣòfin tuntun
Adarí ilé ìgb̀imọ̀ Zamfara, Alhaji Bilyaminu Moriki, ti búra fún ọmọ ilé ìgbìmọ̀ tuntun tí wọ́n dìbò yan, Mustafa Sadauki ti ẹgbẹ́ òsèlú Peoples Democratic Party (PDP), tí ó jáwé olúborí nínú ìbò àdìkù ọjọ́ kẹta,…
Ẹ Lọ Ọ Fọkàn Balẹ̀: Shinkafi Pàrọwà Sí Àwọn Alátìlẹyìn Rẹ̀ Látàrí Àbájáde Èsì…
Ògúnná gbòngbò kan nínú ẹgbẹ́ òsèlú APC, Ọ̀mọ̀wé Sani Shinkafi ti pàrọwà sí àwọn ènìyàn ẹkùn Shinkafi, ìpínlẹ̀ Zamfara láti fọkàn balẹ̀ látàrí àbájáde èsì ìdìbò tí ó wáyé ní ọjọ́ Àbámẹ́ta, ní…
Àtúndì Ìbò Yóò Wáyé Ní Ìpínlẹ̀ Taraba- Àjọ INEC
Àjọ INEC ti sàgbékalẹ̀ àtúndì ìbò ní ìpínlẹ̀ Taraba àti ìpínlẹ̀ Enugu, èyí tí ìrètí wà pé yóò wáyé ní ọjọ́ kẹrìnlá osù kejì
Àjọ INEC sọ ọ̀rọ̀ náà nínú ìfiléde kan tí adarí ètò ìròyìn…
Àjọ Ti Ààrẹ Bú Ẹnu Àtẹ́ Lù Atiku Látàrí Ọ̀rọ̀ Tó Sọ Láìpé Yìí
Ẹ̀ka ti ààrẹ ti bu ẹnu àtẹ lù igbákejì ààrẹ orílẹ̀-èdè yìí nìgbà kan rí, Atiku Abubakar látàrí ọ̀rọ̀ kan tó sọ sí ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ati ìjọba rẹ̀ láìpé yìí.
Oludamọran pataki fún ààrẹ lori ìròyìn àti ọgbọn…
Sénétọ̀ Lawan Kẹ́dùn Ikú Gómìnà Ìpínlẹ̀ Yobe Tẹ́lẹ̀rí, Sénétọ̀ Abba Ibrahim
Ààrẹ Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Nàìjíríà tẹ́lẹ̀rí, Sénétọ̀ Ahmad Lawan ti kẹ́dùn pẹ̀lú ẹbí àti àwọn ènìyàn ipinle Yobe latari iku Gómìnà àkọ́kọ́ alágbádá ipinle naa, Sénétọ̀ Bukar Abba Ibrahim.
Bi iroyin se sọ, Gomina Ipinlẹ Yobe…
Àdìkù ìbò ìpínlẹ̀ Kano: Ọwọ́ Agbófinró tẹ afurasí jàgídíjàgan olóṣèlú
Ọwọ́ sìnkún Agbófinró ìpínlẹ̀ Kano ti tẹ ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ àwọn afurasí jàgídíjàgan olóṣèlú tí wọ́n lò láti fi da ètò àdìkù ìbò rú ní àwọn apá kan ní ìpínlẹ̀ náà.
Kọmiṣọna fun awọn Agbofinro, CP, Mohammed Gumel…
Gbajabiamila gbóríyìn fún ètò ìdìbò, pè fún ìrànlọ́wọ́ láti fòpin sí adigunjalè
Ọ̀gá àgbà fuń àwọn òṣìṣẹ́ ààrẹ Tinubu, Ọ̀gbẹ́ni Fẹmi Gbajabiamila ti gbóríyìn fún ìgbìmọ̀ olómìnira tí ń mójútó ètò ìdìbò lórílẹ̀-èdè, INEC fún bí ó ṣe ṣètò àdìkù ìbò nírọ̀wọ́ rọsẹ̀ ní Surulere…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ebonyi gbóríyìn fún INEC lórí àdìkù ìbò òdodo
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ebonyi, Ọ̀gbẹ́ni Francis Nwifuru ti gbóríyìn fún ìgbìmọ̀ olómìnira tí ń mójútó ètò ìdìbò lórílẹ̀-èdè, INEC fún bí ètò ìdìbò àdìkù ṣe lọ wọ́rọ́wọ́ ní agbègbè Gúsù Ebonyi, ti ìjọba…
Àwọn òsìṣé elétò ààbò, òṣìṣẹ́ INEC gúnlẹ̀ lásìkò fún ìbò àdìkù ní ìpínlẹ̀…
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn òsìṣé elétò ààbò ni ó ti gúnlẹ̀ sí Ikare-Akoko àti àyíká ìlú náà fún àdíkù ìbò fún ipò ilé ìgbìmọ̀ aṣojú fún Àríwá-Gúsù Akoko àti Àríwá-iwọ̀ oòrùn Akoko, ti agbègbè ìjọba…
PDP yan Toyese ní igbákejì alága iwọ̀ oòrùn lápapọ̀
Ìgbìmọ̀ ìsiṣẹ́ lápapọ̀, NWC ti ẹgbẹ́ òṣèlú Peoples Democratic Party, PDP ti gbìmọ̀ pọ̀ yan Ọ̀gbẹ́ni Ajisafe Toyese láti ìpínlẹ̀ Ọṣun ní igbákejì alága iwọ̀ oòrùn lápapọ̀ fún ẹgbẹ́ náà.
Eleyii wa ninu alaye kan ti…