Browsing Category
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
This is a Nigeria news category
Ààrẹ Tinubu túnbọ̀ fìdí ìpinnu rẹ̀ múlẹ̀ lóri ìfọ̀rọ̀jomitoro ọ̀rọ̀ láàrin ẹlẹ́sìn,…
Adarí Nàìjíríà, Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti túnbọ̀ fìdí ìpinnu rẹ̀ múlẹ̀ lóri ìṣàgbélárugẹ àjọṣepọ̀ ìfọ̀rọ̀jomitoro ọ̀rọ̀ láàrin Àwọn ẹlẹ́sìn, ìgbàmọ́ra, àti ìfọwọ́sowọ́pọ̀ jákèjádò lágbàáyé
Ààrẹ naa…
Ààrẹ Tinubu, àwọn adarí àgbáyé kópa nínú ìgorí ìtẹ́ Pope Leo kẹrìnlá
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti darapọ̀ mọ́ àwọn adarí lágbàáyé ni St Peter’s Basilica fún ìgorí ìtẹ́ Pope Leo kẹrìnlá, tí ó fi ìgbà kan jẹ́ àdarí Kadinali Robert Francis Prevost, ó jẹ́ ọmọ bíbí inú Chicago, tí ó sì…
Ètò Ìkànìyàn Ṣe Pàtàkì Fún Ìgbáradì Ọjọ́ Iwájú Nàìjíríà – Ààrẹ Sẹ́nètì
Ààrẹ àwọn Senetọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Sẹ́nétọ̀ Godswill Akpabio ti sọ pé ó pan dandan láti ṣe ètò Ìkànìyàn láti lè jẹ́kí Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà pèsè fún ọjọ́ ọlá èniyàn rẹ.
Sẹ́nétọ̀ Akpabio sọ pé ó ye kí ètò ìkànìyàn náà ti wáyé…
Ọdún Egúngún Lágbayé Ti 2025: Makinde Pinnu Ìgbélárugẹ Àṣà Fún Àgbéga Ọrọ̀ Ajé
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti tẹnu mọ́ pé ìṣèjọba òun yóò máa ṣe atilẹyin fún ìmúgbòòrò àṣà àti ìgbélárugẹ ìṣẹ̀dálẹ̀ ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Gómìnà ló síṣọ lójú ọ̀rọ̀ yìí níbi àṣèkágbá ọdún Egúngún Lágbayé ti ọdún 2025, ayẹyẹ…
Orílè-èdè Nàìjíríà Darapọ̀ Mọ́ Báǹkì Ilẹ̀ Gẹẹsi Fún Àtúnṣe Àti Ìtèsíwájú
Wọ́n ti gba orilẹ̀-ède Nàìjíríà wọlé bí ọmọ ẹgbẹ́ bánkì àjọ European Bank for Reconstruction and Development (EBRD).
Mínísítà ètò owó àti Olùdarí ètò ọrọ̀ ajé, ọ̀gbẹ́ni Wale Ẹdun, ló sọ eléyìí di mímọ̀ níbi Ìpàdé àjọ EBRD ọdún 2025…
Ìpínlẹ̀ Rivers Yoo Tubọ Tẹpẹlẹ Mọ Ètò Ààbò
Ìpínlẹ̀ Rivers ti fi dá àwọn èniyàn rẹ̀ lójú pé àwọn yóò tubọ tẹpẹlẹ mọ́ ètò ààbò ẹ̀mí àti dúkìá wọn káàkiri gbogbo agbègbè náà.
Alábójútó ipinlẹ Rivers, Vice Admiral Ibok-Ete Ibas tó ti fẹ̀yìntì nìdí isẹ́ ológun ló…
Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ti Jẹ̀jẹ́ Pé Àwọn Yóò Tún Ọ̀nà Benin-Sapele Se
Ìjọba Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti sèlérí pé àwọn yóò tún Ọ̀nà Benin-Sapele tó ti bajẹ tó wà ní ìpínlẹ̀ Edo, gúsù Nàìjíríà ṣe ní kíámọ́sá.
Mínísítà ipinlẹ fún iṣẹ ode, Bello Goronyo ló ṣe ileri yìí látàrí ẹ̀bẹ̀ láti ọdọ àjọ…
Ààrẹ Tinubu Yóò Wà Níbi Ìfinijoyè Pope Leo Ẹ̀lẹ́ẹ̀kẹrìnlá
Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Naijiria, Bola Ahmed Tinubu yóò kúrò ní Abuja lọ sí Rome ti ṣe Olu ìlú Italy ní ọjọ́ Àbámẹ́ta láti jẹ ìpè ti wọ́n pèé fún ayẹyẹ Ìfinijoyè Pope Leo Ẹ̀lẹ́ẹ̀kẹrìnlá.
Pope Leo Ẹ̀lẹ́ẹ̀kẹrìnlá tile sọ pé òun nífẹ̀ẹ́ orílè-èdè…
Ààrẹ Nàìjíríà Tí Fọwọ́sí Gbígba Àwọn Ẹ̀ṣọ́ Igbó
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu tí fọwọ́sí ìgbanísíṣẹ́ tí àwọn ẹ̀ṣọ́ igbó gẹ́gẹ́bí isọdọtun àwọn ìlànà orílẹ̀-èdè láti ní Ààbò àti gbá àwọn igbó Nàìjíríà pàdà lọwọ́ àwọn ọ̀daràn àti àwọn arufín ilú.
Ìpinnu náà ní èròngbà látí tẹra mọ iṣẹ́…
Nàìjíríà Ṣé ìfihàn Ìgbésẹ̀ Àtúnṣe Òfin Tí Ọọ̀ràn-Orí-Ayélujára
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí n ṣé àfihàn ìgbésẹ̀ àtúnṣe tí Òfin Ọọ̀ràn-Orí-Ayélujára, gẹ́gẹ́bí Mínísítà fún ìròyìn àti Àlàyé tí Orílẹ̀-èdè, Mohammed Idris, ṣé ìdánilójú imurasilẹ ìjọba láti ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin tí Orílẹ̀-èdè, àwọn…