Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
Àìsàn Ikọ́ Féére Yóò Di Ohun Ìtàn Ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà- Ìjọba Àpapọ̀ Sọ̀rọ̀…
Ìfikùnlukùn pẹ̀lú àwọn aráìlú àti lílo ohun èlò ìgbàlódé ni yóò jẹ́ ọ̀nà àbáyọ pàtàkì láti tán ìsòro àrun ikọ́ féére ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà gẹ́gẹ́ bí ìgbìyànjú tí ó wáyé èyí tí ó mú kí…
Àjọ UNICEF Ṣe Ìrànlọ́wọ́ Ẹ̀rọ Tó Mú Ènìyàn Mí Fún Ìpínlẹ̀ Bauchi.
Àjọ àgbáyé fún ìtọjú àwọn ọmọdé UNICEF ti ṣe Ìrànlọ́wọ́ ẹ̀rọ to n ṣe Ìrànlọ́wọ́ fún ènìyàn láti mi daradara fún ìjọba ìpínlẹ̀ Bauchi.
Aṣojú àjọ UNICEF ni orílè-èdè Nàìjíríà Christian Minute ló sọ èyí di mímọ̀ ni ọjọ ìṣẹgun nígbàtí ó gbé…
NAFOWA Pèsè Ìwòsàn Ọ̀fẹ́ Fún Àwọn Ènìyàn Ìlú Enugu
Kò dín ní igba ènìyàn nínú àwọn olùgbé Abakpa, àgbègbè Enugu tí ó jẹ ànfààní ìwòsàn ọ̀fẹ́, èyí tí àjọ NAFOWA, tí ó jẹ́ àkójọ ìyàwó àwọn ọmọ ogun òfurufú, tí wọ́n se agbátẹrù rẹ̀
Ètò…
Ire Dé : Ìjọba Ìpínlẹ̀ Jigawa Gba Òṣìṣẹ́ Ẹgbẹ̀rún Mẹ́ta Sí Ẹka Ètò Ìlera
Olùbádámòràn Pàtàkì Sí Gómìnà Umar Namadi, Malam Isa Surajo sọ wipe ẹka ètò ìlera ìpínlẹ̀ Jigawa nílò àtúntò tí ó múná dóko, èyí tí yóò mú kí ètò ìlera di ìrọ̀rùn fún mùtú-mùwà ní ìpínlẹ̀ náa…
Ẹ Fọkàn Balẹ̀ : Kòsí Àrùn Ìgbàlódé Covid-19 Variant Ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà: Ìjoba…
Ẹka Ìjọba Àpapọ̀ tí ó ń rí sí ètò ìlera ti fi ọmọ Orílẹ̀-èdè Naijiria lọ́kàn balẹ̀ pẹ̀lú àrídájú wípé àrùn Covid-19 tí ó wà ní apákan àwọn Orílẹ̀-èdè àgbáyé kò sí ní Orílẹ̀-èdè Naijiria. Ìjọba pè…
Ìpínlẹ̀ Delta Fọwọ́sọwọ́pọ̀ Pẹ̀lú Àjọ NEMSAS Fún Ìdàgbàsókè Ọpọlọ Àwọn Ọmọdé Ni Ìpínlẹ̀ Náà.
Nínú igbiyanju ijoba ìpínlẹ̀ Delta láti rí wí àwọn ọmọdé ri ìtọ́jú tó péye pàápàá jùlọ fún ìdàgbàsókè ọpọlọ àwọn ọmọdé.
ìjọba ìpínlẹ̀ Delta fọwọ́sọwọ́pọ̀ Pẹ̀lú Àjọ NEMSAS niyen Àjọ to n mójú tó ìtọ́jú àti ìdàgbàsókè ọpọlọ.
Dọ́kítà…
Ìpolongo Ìfètòsọ́mọbíbí Wáyé Ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀sun
Àjọ kan tí ìgbáyégbádùn ọmọnìyàn jẹ lógún ti bẹ̀rẹ̀ ìpolongo ìfètòsọ́mọbíbí ní àwọn ìlú kéréje-kéréje ní ìpínlẹ̀ Ọ̀sun
Ìgbésẹ̀ náà bẹ̀rẹ̀ ní òpin ọ̀sẹ̀, ní àgbègbè Abesu, ìjọba ìbílẹ̀…
Ẹ Fòpin Sí Ìfipá Báni Lòpọ̀ Àti Àsìlò Ọmọnìyàn Láwùjọ- Akọ́ṣẹ́mọṣẹ́ Kan Kégbàjarè
Agbẹjọ́rò tí ó tún jẹ́ ajàfẹ́tọ̀ọ́mọnìyàn, Toyin Taiwo-Ojo ti kégbàjarè gẹ́gẹ́ bí ìwà ìfipábánilòpọ̀ àti àsìlò ọmọnìyàn se gbilẹ̀ láwùjọ
Ó fi àìdùnnú ọkàn hàn ní ọjọ́ Àbámẹ́ta nígbà tí ó…
Pípèsè Ilé Ìgbọ̀nsẹ̀ Se Pàtàkì láwùjọ- Àjọ Àgbáyé Kan Pàrọwà Sí Ìjọba…
Olùdásílẹ̀ Àjọ Fún Ìpolongo ìpèsè ilé ìgbọ̀nsẹ̀ ní àgbáyé, Ọ̀jọ̀gbọ́n Jack Sim ti rọ ìjọba Orílẹ̀-èdè Naijiria lati pèsè àwọn ilé ìgbọ̀nsẹ̀ tí ó dùn-ún rí- dùn-ún wò pẹ̀lu ìfọwọ́sowọ́pọ̀ àjọ aládàníi…
Ólé Ní Ẹgbẹrin Àwọn Ènìyàn Ni ilu Ibadan Tí Wọ́n Jẹ Anfààní Iṣẹ Abẹ Ọ̀fẹ́.
Ólé ní Ẹgbẹrin Àwọn Ènìyàn ni ìlú Ìbàdàn tí wọn ní jẹ anfààní ìwòsàn ọ̀fẹ́ nípa iṣẹ́ Abẹ láti ọ̀dọ ilé iṣé alaadani tí ẹsìn isalam ti wọn ń pé ni ATF.
Wọ́n ní Ètò iṣẹ́ Abẹ Ọ̀fẹ́ yìí yóò kakiri agbègbè ìlú Oyo fún Àlàáfíà àwọn ènìyàn.…