Browsing Category
ÌRÒYÌN ILẸ̀ ÀFÍRÍKÀ
This is a category for Africa news
Àwọn Méjì Pàdánù Ẹmí Wọ́n Nínú Ìjàmbá Ọkọ̀ Òfurufú Ní Kenya
Ènìyàn méjì ní ìròyìn ṣàfihàn pé ó kú nínú ìjàmbá ọkọ̀ Òfurufú kàn, láàrín ọkọ̀ òfurufú akẹ́kọ̀ọ́ kàn àtí ọkọ̀ òfurufú akérò kàn ní Olú-ìlú Kenya ní Nairobi, àwọn ọlọ́pàá àgbègbè náà sọ ní ọjọ́ Ìṣẹ́gun.
Ìṣẹlẹ̀ náà wáyé ní aago mẹ́wàá…
Somalia Dí Ọmọ Ẹgbẹ́ Ìlà-òòrùn Áfríkà Ní Kíkún
Somalia tí dí ọmọ ẹgbẹ́ Àwùjọ Ìlà-òòrùn Áfíríkà (EAC) ní kíkún.
Níbí ayẹyẹ kúkúrú kàn ní ilè-ìgbìmọ̀ EAC ní Arusha, Tanzania, Mínísítà fún Ìṣòwò tí Somalia, Jibril Abdirashid Haji, bí akọ̀wé Gbogbogbò tí ẹgbẹ́ ṣé àfihàn ìwé ìgbà wọlé…
Àwọn Ọmọ Ológun Ojú Omi Orílè-èdè South Africa Darapọ Láti Wa Ọmọ Ọdún Mefa Obinrin To Sọnù.
Àwọn ọmọ ológun orí omi Orílẹ̀-èdè South Africa ti darapọ̀ báyìí lati ṣe àwárí ọmọ ọdún mẹ́fà to sanu ní Orílẹ-èdè náà.
Ọmọ ọdún mẹ́fà náà ti orúkọ jẹ Joslim Smith ni wọn o ko rí ni iwájú ilé rẹ ni Saldanha Bay, leba near Cape, ni bi…
Orílẹ̀-èdè Zimbabwe: Ìròyìn Ìdẹ́rùbà Àdó Olóró Mu Kí Ààrẹ Wọ Gile Ìrìn Àjò Rẹ
Látàrí Ìdẹ́rùbà àdó olòrò, to mú kí pápákọ̀ òfurufú Victoria Fall dáwọ iṣé dúró ní ọjọ́ ẹtì, èyí ló ṣe okun fa ti Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Zimbabwe náà wọ Gile Ìrìn Àjò rẹ lo sí bí ìpàdé ti yóò ti bawon sọ̀rọ̀.
Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Zimbabwe Edson…
Orílẹ̀-èdè Algeria Se Ìfilọ́lẹ̀ Mọ́sálásí Tí Ó Tóbi Jùlọ Ní Ilẹ̀ Adúláwọ̀ Lẹ́yìn…
Algeria se ìfilọ́lẹ̀ Mọ́sálásí ńlá kan èyí tí ó wáyé lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìpènijà
Àwọn agbaṣẹ́se Orílẹ̀-èdè China ni ìròyìn fi yéwa pé ó se iṣẹ́ náà. Mọ́sálásí Algeria náà ni ó jẹ́ èyí tí òsóóró…
Akọ̀ròyìn Ọmọ Orílẹ̀-èdè French Wọ Àhámọ́ Ní Ethiopia
Wọ́n fi akọ̀ròyìn ọmọ Orílẹ̀-èdè French sí àhámọ́ ní Ethiopia, nígbà tí ó se ìrìnàjò sí Orílẹ̀-èdè náà fún àpérò ilẹ̀ adúláwọ̀ tí ó wáyé láìpẹ́
Antoine Galindo, ẹni tí ó fi ìlu Paris se ibùgbé…
Wọ́n Ṣe Ayẹyẹ Ìkẹyìn Fún Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Namibia.
Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Nàmíbíà, Hage Geingob,ni wọn ti gbè sí inú kòtò fún ayẹyẹ igbẹyin ni Orílẹ̀-èdè rẹ
Iboji isiku Acre ni wọn gbé sí ní ọjọ́ àìkú.
Àwọn ènìyàn jankan-jankan ni Orílẹ̀-èdè Afirika ni won peju-pese síbi osiku náà.
Lára…
Orílẹ̀-èdè Burkina Faso: Àwọn Mẹẹdogun Ló Jáde Láyè Látàrí Ikọlu To Wáyé Ní ilé Ìjọsìn Catholic.
Ó kéré jù ènìyàn mẹ́ẹ̀dógún ló jẹ́ Ọlọ́run nipé nígbà tí àwọn àgbẹbọ kọlu ilé ìjósìn lakọkọ ti wọn jọsin lọ́wọ́
Ìròyìn ní lójú ẹsẹ̀ ni àwọn méjìlá jáde láyè nígbà tí àwọn tó kún náà padà jáde láyè lásìkò ti wọn n toju wọn
Gẹ́gẹ́ bí…
Àjọ ECOWAS Gbóríyìn Fún Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Senegal Fún Bíbọ̀wọ̀ Fún Òfin
Àjọ Economic Community of West African States (ECOWAS) ti gboriyin fún ààrẹ Orílẹ̀-èdè Senegal, Macky Sall, fún gbígba láti ju awà silẹ tí asiko rẹ lori aleefa bá ti pari bi ààrẹ gégé bí òfin se làá kalẹ̀.
Àjọ náà patewo fún…
Orílẹ̀-èdè Kenya Fojú Fo Owó Ìrìnà Ìwọlé Fún Orílẹ̀-èdè South Africans Àti Àwọn Míràn Da.
Orílẹ̀-èdè Kenya ti fojú fo owó Ìrìnà Ìwọlé fún àwọn tó ni ìwé ìrìnnà Pásípọ̀tù láti orílẹ̀-èdè South Africa àti orile-ede mẹ́fà míràn da látàrí ìtakò tó ń jà ràìnràìn awuyewuye ọgbọ̀n owó dọ́là ti won ṣẹṣẹ gbe jade fún àwọn…