Take a fresh look at your lifestyle.

Ìjọba Nàìjíríà Sanwó Ìtanràn Fún Àwọn ènìyàn Mẹ́rìnléláàdọ́rin Tí Àwọn Ọlọ́pàá Fí Ìyà Àìtọ́…

Ìjọba Nàìjíríà tí sàn owo tó jù igba o le mejidinlọgọrin miliọnu naira (289m) fun àwọn mẹrinlelaadọrin (74) lórí bí wọn se tẹ ẹtọ  ọmọniyan  loju mọlẹ ati ẹsun iwa ọdaju tí  awọn ọlọ́pàá kàn hu si wọn . Ìgbìmọ̀ Ìwádìí olómìnira lórí…

EU Ṣé Ìfilọ́lẹ̀ Ètò Láti Ṣé àtìlẹ́yìn fún Ìjọba Awaarawa Ní Nàìjíríà

Àjọ Euroopu (EU) tí ṣé ìfilọ́lẹ̀ ètò kàn látí jẹ́ kí àwọn ará ìlú ní ìgbàgbọ́ àti igbẹkẹle nínú ètò ìdìbòyàn ati Ìjọba Awaarawa ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Gẹgẹ bí àjọ náà ṣé sọ, wọ́n yóò ṣé ìfilọ́lẹ̀ ètò náà ní Ọjọ́ Ajé, Ọjọ Kejìlá, Oṣù…

Ọmọ Ogún Orílẹ̀ Nàìjíríà Yóò Tẹ̀síwájú Láti Máà Fún Àwùjọ Padà – Olórí Ọmọ Ogún

Olórí ẹgbẹ́ ọmọ Ogún (COAS) Lieutenant General Faruk Yahaya sọ pé ọmọ Ogún Nàìjíríà lábẹ́ iṣọ rẹ̀ yóò tẹsiwaju láti fún àwùjọ padà nípa ìfọwọ́sowọ́pọ̀ àti àtìlẹ́yìn tó nípa ti awọn ara ilu n ṣé láti mú òfin ìlú dúró. Nínú àtẹ̀jade…

Ẹgbẹ́ Agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà Fẹ́ Ètò tó Dára Fún Bọ́ọ̀lù Afẹsẹgba Ní ilẹ̀ Nàìjíríà

Ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Nàìjíríà (ANFPU), tí pepe fún ṣíṣe ètò àti ìlànà tó dára jùlọ fún gbogbo ìpele tí bọ́ọ̀lù afẹsẹgba nti orílẹ-èdè náà. Abdul Sule, Alàkóso tí ẹgbẹ́ náà sọ pé, liigi agbabuta gbogbo orílẹ-èdè ní o má n ṣé ìdàgbàsókè…
button