Take a fresh look at your lifestyle.

Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ní dandan jẹ́mánì gbọ́dọ̀ dá gbogbo àwọn nkàn ìṣẹ̀ǹbáyé tí…

Ìjọba Nàìjíríà ti bèèrè fún ìdápadà gbogbo àwọn  ojì-din-lẹwá le ni ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ́fà Idẹ  ti ilu Benin tí wọ́n  gbẹ́sẹ̀ lé  ní orílẹ̀-èdè Áfíríkà ní ọdún 19th, tí wọ́n sì sọ ibùgbé rẹ̀ di   ilé-ìṣọ́ Jẹ́mánì.…

Ilé-iṣẹ́ àwọn ọmọ ogun òfurufú kégbàjarì :’ẹ ṣọ́ra fún ayédèrú ìròyìn gbígba àwọn…

Oludari  Ilé-iṣẹ́ àwọn ọmọ ogun òfurufú (NAF), ti ya ara rẹ̀ kúrò nínú ìkéde tí wọ́n ń pín kiri lórí àwọn ẹ̀rọ ayélujára kan nípa bíbẹ̀rẹ̀ sí ní gba àwọn akẹ́kọ̀ọ́ sí  ilé ẹ̀kọ́ gíga  ti Nọ́ọ́sì, NAFCON. NAF…

Ilé-iṣẹ́ tí ó ń tẹ owó ní orílẹ́-èdè Nàìjíríà fi gbegedé sórí títẹ owó jáde

Olùdarí Alákóso, ilé-iṣẹ́ ìtẹwó ní orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, NSPMC, Abbas Umar Masanawa sọ pé, ilé-iṣẹ́ ọ̀hún ti ṣàṣeyọrí tó lámì nínú títẹ  owó síta ní orílẹ̀-èdè Naijiria. Ile-iṣẹ naa tun ni agbara  lati tẹ…

COAS – Àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà mú ìṣòkan lọ́kùúnkúndùn láti gbógun ti ikọ̀…

Ọ̀gá àgbà fúnilé isẹ  àwọn ọmọ ogun Nàìjíríà (COAS) ,Ọ̀gágun àgbà Faruk Yahaya àti àwọn ọmọ- ikọ̀ rẹ̀ ,ní Mongadishu Cantonment ní ilé ìjọ́sìn kátólíkì ní Àbújá,  ṣàfihàn àwọn ọmọ-ogun Nàìjíríà gẹ́gẹ́…

COVID-19 : Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tún ti rí ènìyàn mẹ́rìndín-lọ́gọ́ta míràn

Ilé-iṣé tó ń mójútó àjàkálẹ̀ ààrùn ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NCDC) sọ pé àwọn ènìyàn mẹ́rìndín-lógún míràn tún ti kún àwọn ẹ̀rin-le-ni-ojì din ni ẹgbẹ́je tó ti ní ààrùn náà tẹ́lẹ̀ lọ́jọ́ àìkú.…

Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti Gáḿbíà fìmọ̀ ṣọ̀kan láti kojú àwọn ọlọ̀tẹ̀.

Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti Gáḿbíà ti buwọ́ lu ìwé àdéhùn lórí ìfọwọ́sowọ́pọ̀ àwọn ọmọ ogun láti kojúu àwọn ọ̀daràn tó ń da orílẹ̀ èdè wọn láàmú. Oludamọran pataki si Minisita fun Aabo, Mohammed Abdulkadri,…

Ètò Oúnjẹ lọ́pọ̀ yanturu yóò gbọn òṣì dànù-igbákejì Òsíǹbàjò

Igbákejì ààrẹ, orilẹ ede Naijria, Ọ̀jọ̀gbọ́n Ọ̀síńbàjò sọ pé,ìgbìyànjú orílè-èdè láti pèsè oúnjẹ lọ́pọ̀ yanturu jẹ́ ọ̀kan pàtàkì lára ilànà láti dẹ́rù bòṣì jákèjádò  orilẹ ede Nàìjíríà. Ọjọgbọn…

Ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin fọwọ́ sí owó ìṣètò ilé-ẹ̀kọ́ gíga Ìmọ̀-iṣé Ìlera àti ti ìmọ̀…

Ilé-ìgbìmọ̀ aṣòfin ti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti fi òǹtẹ̀ lu  àwọn òfin méjì láti dá ilé ẹ̀kọ́ gíga fáfitì àpapọ̀ ìmọ̀ ìlera sáyẹ́ńsì, sílẹ̀ ní Otukpo  ní Ìpínlè Benue àti ti ìmọ̀ ìbáraẹnisọ̀rọ̀…

Ààrẹ orílè-èdè Nàìjíríà kí Orílè-èdè Ṣáínà fún àjọ̀dún ọgọ́rún ọdún ẹgbẹ́…

Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Mùhámmádù Bùhárí ti ránṣẹ́ ìkíni  sí ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ ti orílẹ̀-èdè Ṣáínà, ààrẹ Xi Jinping lórí ayẹyẹ àjọyọ̀  ọgọ́rùún ọdún  tí wọ́n dá ẹgbẹ́ kọ̀múnísítì ti Ṣáínà sílẹ̀.…

Mítà iná mọ̀nàmọ́ná mílíọ́nù mẹ́fà lóti wà nílẹ̀ fún àwọn ará ìlú báyìí

Olùdárí Alákóso, Ilé-iṣẹ́ tó ń  ṣàkóso iná mọ̀nàmọ́ná ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, NEMSA àti ọ̀ga àgbà Olùyẹ̀wò iná mọ̀nàmọ́ná lápapọ̀, Peter Ewesor sọ pé, Ìjọba  ti gbèrò láti gbé  àwọn mítà iná…
button