Olórí Ológun (COAS), Lieutenant General Taoreed Lagbaja, tí ṣé àyẹwò àwọn ọmọ-ogún 401 ní Makurdi, Ìpínlẹ̀ Benue, ní ìtèsíwájú ìrìn-àjò àyẹwò rẹ̀ fún Ìgbàradi wọ̀n ní gbogbo àwọn ẹka tí Ile-iṣẹ́ ológun tí Nàìjíríà.
Èyí jẹ́ apakan nínú àwọn ìgbìyànjú rẹ̀ látí tún mú ẹsẹ àwọn ọmọ-ogún múlẹ sí láti ṣé àdínkù gbogbo italaya ààbò ní Orílẹ̀-èdè náà
COAS ASSESSES TROOPS' COMBAT READINESS IN MAKURDI … Pledges to provide more infrastructure in NA Barracks
The Chief of Army Staff (COAS) Lt Gen Taoreed Lagbaja has paid an operational visit to 401 Special Forces Brigade Makurdi, Benue State on Thursday 30 November 2023, as… pic.twitter.com/ny6We4ddUM
— Nigerian Army (@HQNigerianArmy) November 30, 2023
Nínú ọrọ̀ kàn tí Olùdarí Ibanisọrọ Gbogbo Ọmọ-ogún, Brigadier General Onyema Nwachukwu, sọ pé Olórí Ológun náà ṣé àfihàn ìdùnnú rẹ̀ sí àwọn ọmọ-ogún fún isé takuntakun tí wọ́n ṣé ní ẹ̀kà ààbò orílẹ̀-èdè náà.
General Lagbaja ní Ọjọ́bọ̀, ọgbọn ọjọ́, Oṣù Kọkànlá ọdún 2023, rọ wọ́n látí tẹ̀síwájú lórí ipá wọ́n láti ṣétọ́jú àlàáfíà ní orílẹ̀-èdè náà. O tún rọ̀ wọ́n látí yàgò fún àwọn irúfin lẹ́nu iṣẹ́ .
Leave a Reply