Olórí Àwọn Ọmọ-ogún Ṣé Àyẹwò Ìgbàradi Àwọn Ọmọ-ogún Ní Makurdi
Olórí Ológun (COAS), Lieutenant General Taoreed Lagbaja, tí ṣé àyẹwò àwọn ọmọ-ogún 401 ní Makurdi, Ìpínlẹ̀ Benue, ní ìtèsíwájú ìrìn-àjò àyẹwò rẹ̀ fún Ìgbàradi wọ̀n ní gbogbo àwọn ẹka tí Ile-iṣẹ́ ológun tí Nàìjíríà.
Èyí jẹ́ apakan nínú…