Browsing Category
Ó GBÓNÁ FẸLI-FẸLI
This is a category for LATEST NEWS
Ìyàwó Ààrẹ Nàìjíríà Rọ Ọmọ Orílẹ-èdè Yìí Látì Tẹ́wọ́ Gba Ohun Àlùmọ́nì Agbára
Ìyàwó Ààrẹ Orílẹ-èdè yìí ti rọ àwọn ọmọ orílẹ-èdè yìí látì tẹwọ gba ohun alumọni agbara fún àyíká tó mọ́ tótó.
Ó sọ èyí nibi ọrọ rẹ láti sami sì ayeye ọjọ ayika to mọ́ toto agbaye ọdún 2026.
Arabinrin akọkọ rọ gbogbo ọmọ Naijiria…
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Yóò Gbáradì Ni Scotland Fún Ìdíje Commonwealth– NSC
Àjọ National Sports Commission (NSC), ti sọ àsọdajú pe àwọn eléré ìdárayá Nàìjíríà yóò peju pésẹ̀ nibi igbaradi ọlọ́sẹ̀ mẹ́rin ni orílẹ̀-èdè Scotland latàri Ìdíje Kọ́mọ́wẹ́ẹ̀tì ọdún 2026 to n bọ̀.
Ọgá agba àjọ NSC,…
Ààrùn ibà Dengue ń gbilẹ̀ ní Sokoto, tí ẹ̀mí kan sì lọ síi
Ilé iṣé tí ń rí sí ìmójútó àti ìdènà àjàkálẹ̀ Ààrùn ní Nàìjíríà (NCDC), ti jábọ̀ pé wọ́n ti fura sí ènìyàn mọ́kàndín-lógún tó ní ààrun ibà dengue nínu oṣù kọkànlá 2025, pẹ̀lú àwọn mẹ́f̀a tí…
Igbákejì Ààrẹ Shettima padà sí Abuja lẹ́yìn ìjíròrò lórí ọrọ̀ ajé
Igbákejì Ààrẹ Kashim Shettima ti padà sí Abuja lẹ́yiịn ọ̀sẹ̀ kan gbáko ìjùmọ̀sọ̀rọ̀ àti èròńgbà ọrọ̀ ajé sí Guinea-Conakry àti Switzerland.
Igbakeji Aarẹ Shettima gunlẹ si abala Aarẹ ti papakọ ofurufu kariaye Nnamdi…
Tunisia sọ àwọn gbajúgbajà akọ̀ròyìn méjì sẹ́wọ̀n ọdún mẹ́ta ààbọ̀
Ilé ejọ́ Tunisia dá ẹjọ́ tí ó sì sọ àwọn gbajúgbajà akọ̀ròyìn méjì sẹ́wọ̀n ọdún mẹ́ta ààbọ̀ lórí ẹ̀sùn yíyọ́ owó orí sílẹ̀, tí ìkan lára ẹbì sọ pé ìgbẹ̀san ìjábọ̀ tí wọn ń ṣe ni.
Awọn akọroyin naa, Bohran…
Makinde Ni Okòwò Ti Fẹṣẹ Múlẹ̀ Ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Bí Ladoja, Igbákejì Gómìnà Àti Àwọn Aṣòfin Kan Ṣe…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti sọ di mímọ̀ pé ìṣèjọba òun ti dé ìpele eléyìí to fihàn pé okòwò ti rẹ́sẹ̀ walẹ̀ pẹ̀lú sisan owó tí kò dín ní Bílíọ̀nù Mẹrinlelogun (N24b) gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù òṣìṣẹ́ ni Ìpínlẹ̀ àti Ìjọba Ìbílẹ̀.
Bákan…
Makinde Ni Okòwò Ti Fẹṣẹ Múlẹ̀ Ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ Bí Ladoja, Igbákejì Gómìnà Àti Àwọn Aṣòfin Kan Ṣe…
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti sọ di mímọ̀ pé ìṣèjọba òun ti dé ìpele eléyìí to fihàn pé okòwò ti rẹ́sẹ̀ walẹ̀ pẹ̀lú sisan owó tí kò dín ní Bílíọ̀nù Mẹrinlelogun (N24b) gẹ́gẹ́ bíi owó oṣù òṣìṣẹ́ ni Ìpínlẹ̀ àti Ìjọba Ìbílẹ̀.
Bákan…
Olubadan ní ìgbàgbọ́ nínú ìgbésẹ̀ tí Ààrẹ Tinubu gbé lórí ọ̀rọ̀ ààbò
Ọba ilú Ìbàdàn, Olúbàdàn ti ilẹ̀ Ìbàdàn, Gúsù Iwọ̀ Òòrùn Nàìjíríà, Ọba Rasidi Ladoja, ti sọ pé àwọn ìpeniníjà àìláàbò Nàìjíríà kìí ṣe nǹkan tí kò le di àfìsẹ́yìn, tí ó mọ̀ dájú pé Ààrẹ Bola…
Nàìjíríà, Amẹrika túnbọ̀ fìdí àjọṣepọ̀ ààbo wọn múlẹ̀ fún òmìnira ẹ̀sìn
Ìjọba Nàìjíríà ti túnbọ̀ fìdíi ìfọkànsì rẹ̀ ní́ dídáábòbò ẹ̀mí àti fífi ìdí ààbò rinlẹ̀ jákéjádò orilẹ-ede mulẹ, – lẹ́yìn ìpàdé àpérò Nàìjíríà – Egbẹ Ajọṣepọ Iṣiṣẹ Amẹrika ba agbegbe orílẹ̀-èdè tọrọ naa kan…
Manchester United fìdíẹ̀ múlẹ̀ pé Casemiro ti tẹ̀ síwájú gégẹ́ bíí òpin àdéhùn
Agbábọ́ọ́lù ipò ààrín fún Manchester United, Casemiro, yóò kúrò ní abala Premier League, tí sáà yí bá parí gẹ́gẹ́ bí òpin àdéhùn náà, ilé agbábọ́ọ́lù náà kéde.
Ọmọ ọdun mẹtale-lọgbọn naa le sun ọjọ naa…