Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌLERA
This is a category for health news
Àwọn Ọmọ Òrukàn Jẹ Ànfààní Àlàkalẹ̀ Ìjọba Nípa Ètò Ìlera Ní Ìpínlẹ Gombe
Ẹka tí ó ń mójútó ìrànlọ́wọ́ ìjọba sí ètò ìlera tí ìpínlẹ̀ Gombe (GoHealth) ti bojú àánú wo àwọn ọmọ òrukàn láti jẹ ànfààní ìrànlọ́wọ́ ìjọba nípa ètò ìlera, léyìí tí ìforúkọsílẹ̀ sì ti bẹ̀rẹ̀…
Aya Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kogi Pèsè Ohun Èlò, Ẹ̀bùn Owó Fún Àwọn Aláboyún
Aya Gómìnà Ìpínlẹ̀ Kogi, Hajia Sefinat Ododo ti pèsè ohun èlò, ẹ̀bùn owó àti ohun ìgbáyégbádùn míràn fún igba àwọn aláboyún, àwọn tí ó ń fún ọmọ lọ́yàn, èyí tí ó wáyé ní ọjọ́ ìṣẹ́gun ní ilé ìwòsàn…
Ẹgbẹ́ Rotary International Se Ìrànlọ́wọ́ Fún Àwọn Obìnrin Opó Ní Ìpínlẹ̀ Anambra
Ẹgbẹ́ Rotary, ẹka ti Ìpínlẹ̀ Awka ti se ìrànlọ́wọ́ fún àwọn aláìní, opó, níbi tí àwọn obìnrin opó mẹ́fà ti jẹ ànfààní ẹgbẹ̀rún lọ́nà àádọ́ta fún ẹnìkọ̀ọ̀kan, ní ìlú Awka, Ìpínlẹ̀ Anambra
Ààrẹ ẹgbẹ́…
Salakọ Se Ìrànlọ́wọ́ Àwọn Ohun Èlò Ìlera, Amáyédẹrùn Ní Ìpínlẹ̀ Ogun
Lára ìmọrírì ìgbáyégbádùn ọmọnìyàn, Mínísítà kejì fún Ètò Ìlera, Dókítà Iziaq Adekunle Salakọ ti se agbátẹrù ìsàbẹ̀wò nípa ètò ìlera àti pínpín àwọn ohun èlò amáyédẹrùn fun àwọn eniyan ìjọba…
Ogunlọ́gọ̀ Àwọn Ògo Wẹẹrẹ Ni Ó Gba Abẹ́rẹ́ Àjẹsára Ní Ìpínlẹ̀ Imo Láti Ọwọ́ Àjọ UNICEF
Kò dín ní ẹgbẹ̀rún lọ́nà ọgọ́rùn-ún kan àti mẹ́rìnlá àwọn ògo wẹẹrẹ tí ó jẹ ànfààní abẹ́rẹ́ àjẹsára ní ìpínlẹ̀ Imo, èyí tí àjọ UNICEF se agbátẹrù rẹ
Dókítà Chibuzor Okoroama ni ó sísọ lójú ọ̀rọ̀ náà…
Àrùn Kògbóògùn Aids Yóò Di Ohun Àfìsẹ́yìn Tí Egúngún Ń Fi Asọ Títí Ọdún 2030-…
Ọ̀gá Àgbà Àjọ NACA, Dókítà Temitọpẹ Ilọri ti fi àrídájú hàn pé ìjọba àpapọ̀ ti gbáradì láti fi òpín sí àrùn kògbóògùn, (Aids) ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà títí ọdún 2030
Ilọri sọ ọ̀rọ̀ náà níbi…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Kaduna Ti Gbáradì Láti Gbógunti Jíjẹ Àwọn Oúnjẹ Tí Kò Se Ara Lóore
Ìpínlẹ̀ Kaduna, lábẹ́ àkóso Gómìnà Uba Sani ti gbáradì láti gbógunti jíjẹ ìjẹkúje àti àwọn oúnjẹ tí kò se ara lóòre láwùjọ
Alágba ìgbìmọ̀ tí ó ń mójútó ọ̀rọ̀ oújẹ ní ìpínlẹ̀ kaduna, Mukhtar…
Ìpínlẹ̀ Òsun Ti Gbáradì Láti Mú Ìgbòòrò Bá Ètò Ìlera- Kọmísónà Sàlàyé Ọ̀rọ̀
Kọmísọ́nà Fún Ètò Ìjọba Àpapọ̀ ní Ìpínlẹ̀ Ọsun, Arábìnrin Adenikẹ Adeleke ti sàlàyé pé ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀sun ti se tán láti mú ìdàgbàsókè bá àwọn ilé ìwòsàn alábọ́dé fún ìgbáyégbádùn àwọn ènìyàn…
Ẹgbẹ́ NICRAT Ti Ṣe Àfihàn Ọ̀nà Abayọ Tuntun Fún Ìtọ́jú Àìsàn Jẹjẹrẹ.
Ẹgbẹ́ tó n ṣe ìwádìí nipa àìsàn jẹjẹrẹ (NICRAT) ti ṣe àfihàn ètò tuntun sí ònà abayọ láti borí àìsàn jẹjẹrẹ sí àwọn ènìyàn ní Orílè-èdè Nàìjíríà.
Ọ̀mọ̀wé Musa Gombe ló sọ èyí di mímọ̀ lásìkò ìpàdé àwọn Oníròyìn fún Elétò ìlera ni ìlú…
Àseyọrí Ńlá Ni Ìlàkààkà Gómìnà Ìpínlẹ̀ Anambra Jẹ́ Lójúnà àti Mú Ìdàgbàsókè…
Kọmísọ́nà Fún Ètò Ìkọ́lé Ní Ìpínlẹ̀ Anambra, Ọnọrébù Pauly Onyeka ti gbósùbà fún gómìnà ìpínlẹ̀ Anambra, Ọ̀jọ̀gbọ́n Chukwuma Soludo fún ìlàkààkà rẹ láti mú ìdàgbàsókè bá ẹka ètò ìlera ní ìpínlẹ̀…