Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÁNILÁRAYÁ
This is a category for entertainment news
Àjọ AGN Gbóríyìn Fún Tinubu Bí Ó Se Yan Ọ̀kan Lára Wọn Sí Ipò
Àjọ Actors Guild of Nigeria (AGN) ti gbé ìbẹ́rí fún ààrẹ Tinubu bo se yan ọkan lára ọmọ ẹgbẹ́ rẹ, Ali Nuhu bi ọ̀gá ilé ìṣẹ́ Fiimu Naijiria -Managing Director of Nigeria Film Corporation. Ààrẹ Àjọ AGN, dokita Emeka se igboriyin…
Davido Gbé Gbọ̀ngàn O2 Arena Síta Fún Eré Àìlópin Rẹ̀
Akọrin tàkasùfé ọmọ Nàìjíríà nì ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí David ti gbe gbọ̀ngàn tó gbajumọ̀ - O2 Arena ni Ìlú London síta látàrí ere orin rẹ ti yóò wáyé ni ọjọ kejidinlogbon, osu kínní, ọdún 2024. Lórí òpó ẹ̀rọ X ni wọ́n ti kéde rẹ̀.
Ni…
Burna Boy, Tems Wa Lára Àwọn Ọgọ̀rún Olórin Tó Dára Jùlọ Bí New African Magazine Se Gbekalẹ̀
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ Nàìjíríà ló wa ní ipò òkè bi New African Magazine se gbèe ogorun oruko awon olórin tó lààmì laaka ni ilẹ̀ Adulawọ ti ọdún 2023 jáde.
Ìwé ìròyìn náà gbé ẹnì kọ̀ọ̀kan wọn jáde lati eka bíi oselu, ilé iṣẹ,…
Mo Fi Iṣẹ́ Oṣù Síse Sílẹ̀ Látàrí Owó Oṣù Péréte – Zicsaloma
Ọmọ bíbí Nàìjíríà, Aláwàdà kẹríkerì, Isaac Aloma, ti won mo sí ZicSaloma ti so pe oun je Oluko ni ile iwe gbogbo- nise Kaduna Polytechnic tele ki oun to wa bẹrẹ sí ní sisé apanilẹ̀rín.
Zicsaloma sọ eyi nígbà tí o n dahun ìbéèrè…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Èkó Korò Ojú Sí Títa Àwọn Ohun Mímu Ẹlẹ́rìndòdò AyédèrúÌjọba…
Ìjọba Ìpínlẹ̀ Èkò ti se ìkìlọ̀ fún àwọn ilé ìgbafẹ́ nípa títa àwọn ohun mímu ẹlẹ́rìndòdò ayédèrú
Olùbádámọ̀ràn pàtàkì sí gómìnà lóri ìgbáyégbádùn àti Àṣà, Ọ̀gbẹ́ni Idris Aregbe ni ó fi…
Gbajúmọ̀ Òṣèré Yoruba Kú Ní Ẹni Ẹ̀tàléláàdọ̀rin Ọdún
Gbajúgbajà Òṣèré Yorùbá nì, Deji Akinremi, ti gbogbo ènìyàn mọ̀ sí “Ọlọ́fà Iná” ti papòdà ní ẹni ọdún.
mẹ́tàléláàdọ̀rin.
Òṣèré, Saidi Balogun gbèe jáde lórí Instagramu (@saidibalogun) rẹ̀ pé awó ti lọ ni ọjọ́ Ọjọ́bọ̀. Ó kọ…
N Kò Ní Padà Sí Ìdí Iṣẹ́ Orin Kíkọ– Britney Spears
Akọrin orílẹ̀-èdè Amẹ́ríkà àti olùkọrin sílẹ̀, Britney Spears lọ sí ojú òpó instagramu rẹ̀ ni ọjọ́ Ọjọ́rú láti takò ìròyìn tó ń jà ràìn-ràìn pé òun yóò padà sí ìdí orin, ó jẹ́ kó di mímọ pé, òun kò ni padà.
".Gbogbo ìròyìn náà,…
Àwọn Alẹ́nulọ́rọ̀ Pè Fún Gbígbé Àṣà Lárugẹ Àti Pípa Àwọn Ohun Ìṣẹ̀ḿbáyé Mọ́ Fún…
Àrọwa ti wá fún àwọn tí ọ̀rọ̀ kàn láti dáàbò bo Àṣà, gbé àṣà lárugẹ àti fún àsepọ̀ tí ó dán mánrán láàrin àwọn ẹ̀yà gbogbo fún ìbágbépọ̀ àlàáfíà jákè-jádò Orílẹ̀-èdè àgbáyé
…
Mínísítà Rawọ́ Ẹ̀bẹ̀ Ìrànlọ́wọ́ Fún Zack Orji Ẹni Tí Ó Wà Ní Ipò Àìlera
Mínísítà Fún Àṣà Àti Ohun Ìsẹ̀ǹbáyé, Hannatu Musawa ti késí gbogbo ọmọ Nàìjíríà láti se ìrànlọ́wọ́ fún gbajú-gbajà òsèré Zack Orji tí ó wà ní ipò àìlera lẹ́yìn ìgbà tí ó se iṣẹ́ abẹ Orí ní ọjọ kini…
Davido Pẹ̀lú Aya Rẹ̀ Ń Yọ̀ Sẹ̀sẹ̀ Nígbà Tí Wọ́n Sàfihàn Àwọn Ìbejì Tí Olódùmarè Fi…
Davido se ìfiléde fán-án-rán fídíò èyí tí ó sàfihàn Òun, Aya rẹ̀ Chioma àti àwọn ìbejì tí Olódùmarè fi ta wọ́n lọ́rẹ níbi tí àwọn ọ̀tọ̀nkùlú ènìyàn ti dunnú pẹ̀lú wọn
David Adeleke tí gbogbo…