Browsing Category
ÌRÒYÌN ÀṢÀ ÀTI ÌṢE YORÙBÁ
This is a category for culture and life news
Ọ̀jọ̀gbọ́n Soyinka Polongo Gbígbé Èdè Àbínibí Ilẹ̀ Wa Lárugẹ
Ọ̀jọ̀gbọ́n Wole Soyinka-"Nobel Laureate", ti tẹnumọ bó ṣe se pàtàkì láti gbé èdè abínibí ilẹ̀ wá àti àṣà òjogúnbá lárugẹ, wípé ó jẹ́ ohun ìwúlò pàtàkì fún ìdàgbàsókè orílẹ̀-èdè .
Ó sọ èyí ní ọjọ́ Ajé níbi ti o ti ń dáhùn ìbéèrè láti ọdọ…
Ọ̀sẹ̀ Àṣà Ìlú Ìbàdàn Tí 2025: Makinde Ṣèlérí Láti Fún Àwọn Olórí Ìlú Ní Ẹ̀tọ́ Wọn.
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti ṣèlérí pé ìṣèjọba òun kò ní fi ẹ̀tọ́ àwọn olórí ìlú dùn wọ́n.
Gómìnà ló sọ ọ̀rọ̀ yii di mímọ̀ níbi àṣèkágbá ayẹyẹ ọsẹ̀ àṣà ìlú Ìbàdàn to wáyé ni pápá ìṣeré Obafemi Awolowo, ni agbègbè Òkè-Ado, ni ìlú…
Ọdún Egúngún Lágbayé Ti 2025: Makinde Pinnu Ìgbélárugẹ Àṣà Fún Àgbéga Ọrọ̀ Ajé
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti tẹnu mọ́ pé ìṣèjọba òun yóò máa ṣe atilẹyin fún ìmúgbòòrò àṣà àti ìgbélárugẹ ìṣẹ̀dálẹ̀ ni Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Gómìnà ló síṣọ lójú ọ̀rọ̀ yìí níbi àṣèkágbá ọdún Egúngún Lágbayé ti ọdún 2025, ayẹyẹ to…
Ọ̀nà Àbáyọ Si Ìdájọ Òdodo Àti Ìpẹ̀tù Sí Aáwọ̀: Aláàfin Ọ̀yọ́ Pé Fún Ìbáṣepọ̀ Láàrin Àṣà Yorùbá Àti…
Aláàfin ti Ìlú Ọ̀yọ́, Ọba Akeem Abímbólá Owoade I ti tẹnu mọ́ pé òun dúró digbí lórí èrò rere tí òun ni fún àwọn èniyàn Ìlú Ọ̀yọ́ àti ilẹ Yorùbá.
Ọba Owoade , ẹni tó sọ di mímọ̀ pé ọ̀nà kan gbòógì láti mú àdínkù dé bá ìpèníjà to n kojú…
Gowon Tún Ṣèlérí Látí Tọjú Ìtàn Àjogúnbá Nàìjíríà
Ọkàn nínú àwọn àgbà Ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti Olórí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà nígbà kán rí, General Yakubu Gowon, tí tún ṣé ìdánilójú rẹ̀ láti ṣé ìtọjú àwọn ìtàn àjogúnbá Nàìjíríà.
Gen. Yakubu Gowon sọ èyí nígbàtí Ẹgbẹ́ Akọtan tí…
Aláàfin Ìlú Ọ̀yọ́ Ṣe Ìpàdé Pẹ̀lú Àwọn Oṣiṣẹ Ààfin, Pé Fún Ìsọ̀kan Láàrin Wọn
Aláàfin ìlú Ọ̀yọ́, Ọba Abímbólá Akeem Owoade I ti jẹ kó di mímọ̀ pé ìbáṣepọ̀ láàrin àwọn òṣìṣẹ́ kò ṣeé fi ọwọ́ rọ́ sẹ́yìn.
Ọba Owoade tẹnu mọ́ pé ìbáṣepọ̀ tó dan mọ́ọ́rán ṣe pàtàkì fún isé àti iṣẹ́ ojoojúmọ́, tó sì tún jẹ́ ọ̀pákútẹ̀lẹ̀ fún…
Aṣòfin Oluremi Tinubu Pé Fún Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Olori Ìlú Láti Fòpin Sí Dídá Abẹ Fún Ọmọbìnrin (FGM)
Àyà Ààrẹ Orilẹ Èdè Nàìjíríà, Aṣòfin Oluremi Tinubu ti ké sí àwọn Olórí ìlú àti agbègbè láti sa ipá wọn lójúnà àti fi òpin sí dídá abẹ fún ọmọ obìnrin (FGM), kòkòrò HIV/AIDS àti àrùn jẹ̀dọ̀jẹ̀dọ̀.
Oluremi Tinubu lo fi ọ̀rọ̀ lédè lásìkò tó…
Gómìnà Adamawa Ṣé Ìlérí Àtìlẹ́yìn Fún Àwọn Ilé-iṣẹ́ Ìbílẹ̀
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Adamawa, Ahmadu Fintiri, tí tún fí ìdí rẹ̀ múlẹ̀ sí látí ṣé àtìlẹ́yìn fún àwọn ilé-iṣẹ́ ìbílẹ̀ fún pàtàkì ìdàgbàsókè ìpínlẹ̀ náà àti Orílẹ̀-èdè lápapò.
Gómìnà sọ èyí dí mímọ̀ l'àkókò ayẹyẹ Ọjọ́ Ọdún àpapọ̀ Nnoma-Jhar ti…
Mínísítà Àṣà Kí Àlàáfín Tuntun Ti Ìlú Ọ̀yọ́ Kú Oríire
Mínísita orílè-èdè yìí fún àṣà, iṣẹ, Ìrìn-àjò òun igbafe àti ọgbọ́n àtinúdá ọrọ̀ ajé, Hannatu Musawa ti kí Àlàáfín tuntun ti Ìlú Ọ̀yọ́, Ọba Abimbola Akeem Owoade, kú oríire, ti ìgorí ìtẹ́ baba rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Aláàfin…
Ìṣèjọba Mi Koni Tojú Bọ Ìlànà Yíyan Ọmọ Oyè – Makinde
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde tí jẹ ko fi mímọ̀ pé ìṣèjọba òun yóò tẹ síwájú láti máa tẹlé ìlànà tó tọ nínú ìṣàkóso Ìpínlẹ̀ náà
Bákan náà ló ṣàlàyé pé ìṣèjọba òun kò ní tojú bọ ọba jíjẹ àti ìlànà yíyan ọmọ oyè ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́.…