Browsing Category
ÌRÒYÌN ÌDÓKOÒWÒ
This is a category for business news
Ààrẹ Bola Tinubu tí kí Ààrẹ Ẹgbẹ́ Dangote, Alhaji Aliko Dangote, lórí yíyàn rẹ̀ sí ilé-iṣẹ́ ìdókòwò…
Ààrẹ Bola Tinubu tí kí Ààrẹ Ẹgbẹ́ Dangote, Alhaji Aliko Dangote, lórí yíyàn rẹ̀ sí ilé-iṣẹ́ ìdókòwò aládàáni ti banki àgbáyé.
Ilé-iṣẹ́ Ìdókòwò Aládàáni tí Bánkì Àgbáyé jẹ́ 'apá kán tó níí ṣé pẹ̀lú ìgbéga ìdókòwò àti ṣiṣẹda iṣẹ́ ní…
GENCOS Dúnkookò Òkùkùn Biribiri Látàrí Gbèsè Àwọn Oníbàáárà
Àjọ Gencos ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti palrọwà sí ìjọba àpapọ̀ àti àwọn alẹ́nulọ́rọ̀ láti wá ojútùú sí ìsòro gbésè iná mọ̀nàmọ́ná tí wọ́n pèsè àti èyí tí àwọn oníbàáárà rẹ̀ lò
Alága…
Makinde Ke Sí Ọmọ Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà Láti Wá Dá Okòwò Sílẹ̀ Ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti ké sí ọmọ Orílẹ̀ Èdè Nàìjíríà láti wá da okòwò sílẹ̀ ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, nígbà tó fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé Ìpínlẹ̀ náà wà lójú iṣẹ́ lójúnà àti mú kí ọrọ̀ àjé gbèru síi nípasẹ̀ ètò ìgbáyé-gbádùn.
Makinde ló…
Àjọ SON Fún Ilé Iṣẹ́ Tó Wà Ní Anambra Ní Ìwé Ẹ̀rí
Àjọ Standards Organisation of Nigeria (SON) ti fun Ile iṣẹ mẹ́rìnlélógójì ní ìwé èrí Mandatory Conformity Assessment Programme (MANCAP) moyege.
Wọ́n pín ìwé ẹ̀rí náà ní ọjọ́ Ọjọ́bọ̀ ní ìlú Awka, Dókítà Ifeanyi Okeke…
Ìdókòwò Alábọ́dé Ni Ọ̀pákùtẹ̀lẹ̀ Ọrọ̀ Ajé Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà – Mínísítà Jumokẹ…
Mínísítà Fún Ilé Iṣẹ́, Òwò àti Ìdókòwò ti sàfirinlẹ̀ ipa tí ìsòwò alábọ́dé ńkó gẹ́gẹ́ bí ọ̀pákùtẹ̀lẹ̀ èyí tí ó ń mú ìdàgbàsókè bá ètò ọrọ̀ ajé Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà
Nígbà tí ó ń…
Ìgbáyégbádùn Ọmọnìyàn Se Pàtàkì Lásìkol Yìí Àti Ní Ọjọ́ Iwájú – Arábìnrin…
Alámójútó àpapọ̀ fún ìgbáyégbádùn ọmọnìyàn ẹka tí gúsù Ilà oòrùn, èyí tí ó kó ìpínlẹ̀ Anambra, Enugu Imo, Abia, Ebonyi, sínú, arábìnrin Francisca Obialor ni ó sàlàyé pàtàkì ẹ̀tọ́ olùrajà àti…
Àjọ ECOWAS Pè Fún Níná Owó Kan Ṣoṣo Ní Iwọ̀ Òrùn Adúláwọ̀
Mínísítà Fún Ètò Ìnáwó àti Gómínà Báńkì Àpapọ̀ àwọn Orílẹ̀-èdè àjọ ECOWAS ni ó ti pè fún ìdásílẹ̀ owó kan ṣoṣo fún àjọ náà èyí tí yóò se àmúgbóòrò ètò ọrọ̀ ajé àti ìgbáyégbádùn…
Aṣáájú Nàìjíríà Jẹ́jẹ̀ẹ́ Láti Sápá Òun Síi Lórí Ààbò Oúnjẹ
Ààrẹ Nàìjíríà, Bola Ahmed Tinubu tí ṣé ìlérí láti túbọ̀ sápá òun sí lórí àṣeyọrí oúnjẹ, ìdókòwò àti ìdàgbàsókè jákèjádò orílẹ̀-èdè náà.
O ṣé ìlérí náà ní Abuja, Olú-ìlú Orílẹ-èdè l'àkókò tí gbogbo àwọn ọmọ 'All Progressive Congress…
Ààrẹ Tinubu Ṣèlérí Láti Dúró Fún Ètò Ọrọ-Àjé Tó Dára Fún Nàìjíríà
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu tí ṣèlérí láti ṣé ìtọ́jú ètò ọrọ-àjé Nàìjíríà, èyítí yóò ṣé adínkù nínú owó oúnjẹ, pàápàá júlọ l'àkókò àwẹ Ramadan yìí.
Ààrẹ Tinubu sọ èyí lásìkò tó n sọrọ níbí ìpàdé Ìgbìmọ̀ Aláṣẹ tí ẹgbẹ́ òṣèlú tí 'All…