Ààrẹ Tinubu Rọ̀ Àwọn Ènìyàn Láti Dibò Alalafia Ní FCT, Kano, Àti Ipinlẹ Rivers
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu ti rọ àwọn olùdìbò tó yẹ ní Federal Capital Territory (FCT), Kano àti Rivers láti kópa nínú ìdìbò ní ọjọ́ Àbámẹ́ta láìsí ìbẹ̀rù, ó ń ké sí àwọn òṣèlú láti yẹra fún ìwà ipá àti ìwà ìgbónára.
Nínú ìkéde kan…