Àwọn ènìyàn mẹ́rìnlé-lọ́gọ́ta míràn tún ti ní ààrùn covid
Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tún ti rí ènìyàn mẹ́rìnlé-lọ́gọ́ta tuntun tó ṣẹ̀ṣẹ̀ kó ààrùn covid.
Ile-iṣẹ to n mojuto ajakalẹ aarun ni orilẹ-ede (NCDC ),ni o kede rẹ lorii bo ṣe n lọ.Ile iṣe naa sọ pe, awọn eniyan…