Take a fresh look at your lifestyle.

Nàìjíríà yóò ya Ọjọ́ kan sọ́tọ̀ gẹ́gẹ́ bíi ọjọ́ àyájọ́ Fún Àwọn Àgbàlagbà Láìpẹ́…

Mínísítà fún ètò ọmọnìyàn, gbígbógun ti Àjálù àti Ìdàgbàsókè Àwùjọ, Hájìyá Sàdíyá Umar Farouq, ti fidánilójú pé, wọ́n yóò kéde yíya ọjọ́ kan pátákí sọ́tọ̀ fún àwọn àgbàlagbà láìpẹ́. Farouq mu…

Ìjọba Nàìjíríà ṣe ìlérí pé òhun yóò jẹ́ kí abẹ́rẹ́ àjẹsára covid wà lárọ̀wọ́tó

Ìjọba orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti ṣe ìlérí láti ríi dájú pé  abẹ́rẹ́ àjẹsára covid wà lọ́pọ̀ yanturu jákèjádò orílẹ̀-èdè náà. Akọwe  ijọba apapọ ati alaga,igbimọ alakoso aarẹ lori aarun covid,Boss Mustapha,fidi…

Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà kí ààrẹ orílẹ-èdè Zambia tí wọ́n dìbò yàn kú oríire

Ààrẹ Mùhámmádù Bùhárí  kí Ààrẹ orílẹ̀-èdè Zambia, Hakainde Hichilema kú oríire lórí àṣeyọrí rẹ̀ nínú ìdìbò ààrẹ, ọjọ́ kejìlá, oṣù kẹjọ, ọdún 2021. Aarẹ gbe oriyin fun awọn ọmọ orilẹ-ede naa bi wọn ṣe tu…

Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Yóò borí ogun tó n dojúkọ ètò Ààbò àti ọrọ̀-ajé àwùjọ…

Igbákejì ààrẹ, orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, ọjọgbọn  Yẹmí Ọ̀sínbàjò ti  sọ pé, orílẹ̀-èdè Nàìjíríà yóò borí ogun tó n dojúkọ ètò ààbò àti  ètò-ọrọ̀-ajé, tí gbogbo nǹkan yóò sì gún régé fún  àwọn ará…

Ìgbìmọ̀ Ilé-aṣòfin rọ Àwọn Onísègùn Olùgbe Láti fòpin sí ìyanṣẹ́lódì

Ìpaldé ìdúnàádúrà ọlọ́jọ́ méjì tí ilé-ìgbìmọ̀ aṣofín fún Àwọn iṣẹ́ Ìlera ṣe pẹ̀lú ìpinnu láti fòpin sí ìdaṣẹ́sílè tí àwọn ọmọ ẹgbẹ́ oníṣègùn olùgbé jákèjádò orílẹ̀-èdè NARD,bẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́…

Ìgbìmọ̀ aláṣẹ Nàìjíríà gbóríyìn fún Mínísítà fún Iṣẹ́ -ọ̀gbìn tí ó dolóògbé

Àwọn ọmọ ìgbìmọ̀ aláṣẹ ní ọjọ́ọ́rú, gbóríyìn fún mínísítà fún iṣé-ọ̀gbìn ní orílẹ̀-èdè nígbàkan rí,tí ó dolóògbé ní ọjọ́ Àìkú. Akowe fun Ijọba apapọ, Ọgbẹni Boss Mustapha kede iku Malami Buwai,tii  ṣe ẹni…

Orílè -èdè Nàíjíríà ní òhun kò yíhùn padà lórí àtisètọ́jú Àwọn Obìnrin àti…

Ìjọba orílẹ̀ -èdè Nàìjíríà ti tún ìpinnu rẹ̀ ṣe láti kojú áwọn ọ̀ràn tí ó kan Àwọn obìnrin àti àwọn ọmọdé tí ó ní àìlera jákèjádò. Akowe igbagbogbo, Ile-iṣẹ  Omoniyan, Isakoso Ajalu ati Idagbasoke Awujọ,…
button