ÌRÒYÌN YÀJÓ-YÀJÓ
- Àwọn Àgbẹ̀ Olóhun Ọ̀sìn Pè Fún Ìtèsíwájú Nípa Fífún Àwọn Ọmọ Ilé Ìwé Ní Oúnjẹ.
- Fifi Orukọ Sílẹ Àti Síìnù: Àwọn Ènìyàn Tako Ọjọ́ Etí Láti Jẹ Ọjọ́ Ti Won Fi Oruko Kalẹ̀ Gbèyìn
- Faye Ló Gbé Gbà Orókè Nínú Ìdíje Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Senegal
- Àwọn Ènìyàn Tó Tó Ẹgbẹrun Mẹ́fà Lo Jẹ Anfààní Ètò Ìtọjú Ìlera Ọ̀fẹ́ Ni Ìpínlẹ̀ Imo.
- Gómìnà Ìpínlẹ̀ Abia Rọ Àwọn Ènìyàn Láti Wa Ṣe Ìtọ̀jù Àwọn Ọmọ Tó Ní Ìpẹ̀níjà Ará.
- Ẹgbẹ́ Àwọn Ọmọ Ológun Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Sìn Oku Àwọn Ènìyàn Wọn Ti Won Pa Ni Ìpínlẹ̀ Delta.
- Gómìnà Ondo yan àwọn Kọmíṣọ́nà tuntun méjìlá
- Òkú àwọn ọmọ ológun tí wọ́ pa lẹ́nu iṣẹ́ gúnlẹ̀ sí Itẹ́ àwọn ológun Abuja
- Ìjọba Nàìjíríà pinnu láti fààyè ìrọ̀rùn àwọn ọ̀dọ́
- Ìpànìyàn Okuoma: Ààrẹ Tinubu yẹ́ àwọn tó fẹ̀mí wọn lélẹ̀ sí pẹ́lu àmì ẹ̀yẹ orílẹ̀-èdè
ÌRÒYÌN ÀGBÁYÉ
Àwọn orílẹ̀-èdè EU gba Palestine ní orílẹ̀-èdè
Spain pẹ̀lú àwọn adarí Ireland, Malta, àti Slovenia ti gbá láti gbé ìgbésẹ̀ àkọ́kọ́ ní rírí Palestine…
Orílẹ̀-èdè China Àti Angola So Yigi Àjọṣepọ̀ Tó Múná Dóko Pọ̀
Ààrẹ orile-ede China, Xi Jinping se ìpàdé pọ pẹlu ààrẹ Angola, Joao Lourenco ni ilu Beijing.
Ọ̀gbẹ́ni…
Wọ́n Ju Èniyàn Mẹ́sàn án Sí Àtìmọ́lé Látàrí Ìkọ̀lù Sí Àgọ́ Ọlọ́pàá
Ènìyàn mẹ́sàn án ni wọn ti ju sinu akolo olopaa latari ikọlu sí agọ́ olopaa ni agbegbe Paris ni ale ọjọ Àìkú…
Yulia Rọ́ Àwọn Aráàlú Russia Látí Darapọ̀ Mọ́ọ̀ Gẹ́gẹ́ Bí Alátakò Ní Ọjọ́ Ìdìbò
Yulia Navalnaya, opó àdarí àwọn alátakò Alexei Navalny, tí pé àwọn aráàlú Orílẹ̀-èdè Russia látí darapọ̀ mọ́ọ̀ fún…
ÌRÒYÌN ÀṢÀ ÀTI ÌṢE YORÙBÁ
Mínísítà Rọ Àwọn Amúlùúdùn Láti Gbé Àṣà Wa Lárugẹ.
Mínísítà fún àṣà, àti ìṣe wà, Amòfin Hannatu Musa Musawa tí gbà àwọn Amúlùúdùn Làmọ̀ràn láti túnbò teramọ́…
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Abia Rọ Àwọn Ènìyàn Láti Wa Ṣe Ìtọ̀jù Àwọn Ọmọ Tó Ní Ìpẹ̀níjà Ará.
Olùbàdámọ̀ràn pàtàkì fún Gómìnà ìpínlẹ̀ nípa àwọn ènìyàn tó ní Ìpẹ̀níjà Ara, Ògbéni David Anyaele ti rọ àwọn…
ÌRÒYÌN ÁFÍRÍKÀ
Faye Ló Gbé Gbà Orókè Nínú Ìdíje Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Senegal
Èsì Ìdìbò Ààrẹ Orílẹ̀-èdè Senegal ni ọjọ́ ìsinmi ọjọ́ kerinlelogun oṣù kẹta ọdún 2024, fi hàn wí pé Bassiro Diomaye…
ÌRÒYÌN ÒSÈLÚ
Gómìnà Ondo yan àwọn Kọmíṣọ́nà tuntun méjìlá
Gómìnà ìpínlẹ̀ Ondo Lucky Aiyedatiwa, ti fi ìwé orúkọ àwọn Kọmíṣọ́nà méjìlá mìíràn ránṣẹ́ sí ilé ìgbìmọ̀ ìpínlẹ̀ fún ìfìdí múlẹ̀. Ọga agba Akọwe fun eto iroyin si Gomina, Ọgbẹni Ebenezer Adeniyan, sọ eyi ninu…
Ọ̀nà Ṣíṣe: Ìgbìmọ̀ Fọwọ́ Sí Tírílọ̀nù Kan Ó Lé Náírà
Ìjọba orílẹ̀-èdè yi ti fọwọ́ sí Tírílọ̀nù Kan Ó Lé diẹ (N1.267 Trilion) Náírà lati ṣe ọ̀nà àti afárá méjìdínlọ́gbọ̀n jákèjádò Orílẹ̀-èdè yìí.
Mínísítà ọrọ nipa Iṣẹ, Dave Umahi ló sọ eyi nibi to ti n sọ fún oniroyin ilé ààrẹ…
Ilé Ìgbìmọ̀ Asofin Fẹ́ Àjọṣepọ̀ Lórí Ọrọ̀ajé Ìmọ̀ Ẹ̀rọ Àti Èyí Tó Jẹmọ́ Omi
Ikọ̀ Nàìjíríà nibi àjọ Assembly of the Inter-Parliamentary Union (IPU) Ẹ̀lẹ́ẹ̀kejì dínláàdọ̀talélọ́gọ̀rún irú rẹ ti ààrẹ ilé ìgbìmọ̀ aṣofin Godswill Akpabio ṣáájú rẹ̀
ti béèrè fún àjọṣepọ̀ àjọ World Trade Organisation (WTO) ni…
Anambra 2025: Mo ṣetán láti lé Soludo dìde– Ozigbo
Ààrẹ tẹ́lẹ̀ rí ti ó tún jẹ́ Aláṣe àgbà ti ilé iṣẹ́ Transnational Corporation of Nigeria PLC (Transcorp), Valentine Ozigbo, ti sọ pé òun ti ṣetán láti lé gómìnà tó wà lórí oyè Ọ̀jọ̀gbọ́n Soludo dìde.
Ozigbo ti o jẹ…
ÌRÒYÌN ÌDÁNILÁRAYÁ
Obìnrin Ọmọ Nàìjíríà Tó Ń Wakọ̀ Bọ̀ Láti London Sí Ìlú Èkó Ní Ìjàmbá
Obìnrin Ọmọ Nàìjíríà arìnrìn-àjò afìtànbalẹ̀ , Pelumi Nubi, tó fẹ fitan balẹ, nipa ìrìnàjò rẹ lati ilu London s ìlú…
ÌRÒYÌN ÌLERA
Àwọn Ènìyàn Tó Tó Ẹgbẹrun Mẹ́fà Lo Jẹ Anfààní Ètò Ìtọjú Ìlera Ọ̀fẹ́ Ni Ìpínlẹ̀…
Ó kéré jù àwọn ẹgbẹrun mẹ́fà ènìyàn ní yóò jẹ anfààní ètò ìtọjú ìlera Ọ̀fẹ́ ni ìpínlẹ̀ Imo èyí tí Mbana National…
Mílíọ̀nù Méjìàbò Ènìyàn Ilẹ̀ Adúláwọ̀ Lùgbàdì Àìsàn Ikọ́ Féére…
Àjọ WHO ti sàlàyé pé, ó lé ní mílíọ̀nù méjì-àbọ̀ tí ó lùgbàdì àìsàn ikọ́ féére ní ilẹ̀…