Take a fresh look at your lifestyle.
Browsing Category

ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ

This is a Nigeria news category

Mínísítà Fún Iṣẹ́ Nàìjíríà Bú-Ẹnu-Àtẹ-Lú Ìwà Ìbàjẹ́ Ni Òpópónà Èkó Sí Calabar

Mínísítà fún Iṣẹ́ ní Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, Dave Umahi, tí bú-ẹnu-àtẹ-lú àwọn ìwà ìbàjẹ́ àwọn ènìyàn ní òpópónà Èkó sí Calabar, Ó sí kìlọ̀ pé ọwọ́ òfin yóò mú àwọn tó ń hu ìwà ìbàjẹ́ náà. ‎ ‎ Mínísítà ṣe ìkìlọ náà nígbà àyẹwò iṣẹ rẹ̀ ní…

Ìpínlẹ̀ Oyo fọwọ́ sí Àdéhùn Pẹ̀lú ilé Iṣẹ́ iṣẹ́ Agbára

Ìjọba Ìpínlẹ̀ Oyo, nípasẹ̀ Ilé Iṣẹ́ Àyíká àti Àwọn Ohun Àdánidá, ti fọwọ́ sí àdéhùn pàtàkì kan pẹ̀lú ilé iṣẹ́ agbára kan, tí a fẹ́ mú kí àwọn ètò àti ìlànà ojúọjọ́ rẹ̀ lágbára sí i, tí ó dojúkọ ìṣàkóso àyíká Kọmíṣọ́nà fún Àyíká àti Àwọn…

Báńkì fún Iṣẹ́ Àgbẹ̀ Gbóríyìn fún Ìgbìyànjú Ìyàwó Àkọ́kọ́ Lórí Oúnjẹ Tí Kò Péye

Olùdarí Àgbà fún Báńkì fún Iṣẹ́ Àgbẹ̀, Ayo Sotinrin ti gbóríyìn fún àwọn ètò iṣẹ́ àgbẹ̀ àti oúnjẹ tí Ìyàwó Àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà, Sẹ́nétọ̀ Oluremi Tinubu, ṣe, ó sì ṣàpèjúwe wọn gẹ́gẹ́ bí àwọn ìgbòkègbodò tó lágbára tó ń mú ààbò oúnjẹ lágbára…

Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Àti  Orílẹ̀-èdè Jámánì Ṣèlérí Ìfọwọ́sowọ́pọ̀ Nínú Agbára, Ààbò, Àti Ọ̀nà ojú…

Ààrẹ Bola Tinubu àti Aláṣẹ Orílẹ̀-èdè Jámánì Friedrich Merz ti pinnu láti mú kí àjọṣepọ̀ àárín gbùngbùn lágbára sí i àti láti mú kí àjọṣepọ̀ pọ̀ sí i nínú ààbò, agbára, àti àwọn ẹ̀ka ọkọ̀ ojú irin. Nínú ìjíròrò lórí tẹlifóònù, àwọn olórí…

Àjọ NIMC Yóò Bẹ̀rẹ̀ Ìforúkọsílẹ̀ Ní gbogbo orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Pátá.

Ìgbìmọ̀ Ìṣàkóso Ìdánimọ̀ ti Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà (NIMC), sọ wí pé ó ti múra tán láti bẹ̀rẹ̀ ìforúkọsílẹ̀ ní ìpele gbogbo orílẹ̀-èdè  Nàìjíríà fún ìforúkọsílẹ̀ Nọ́mbà Ìdánimọ̀  (NIN) ní ìbámu pẹ̀lú àṣẹ Ààrẹ tí ó pàṣẹ fún Ìgbìmọ̀ Ìṣàkóso…

Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Ṣe Àjọyọ̀ Pẹ̀lú Orílẹ̀-èdè Gambia Fún Àyájọ́ Ọjọ̀ Òmìnira

Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti fi ìkíni ayọ̀ hàn sí Ìjọba àti àwọn ènìyàn  Orílẹ̀-èdè Gambia bí orílẹ̀-èdè náà ṣe ń ṣe ayẹyẹ Ọjọ́ Òmìnira rẹ̀, tí wọ́n ń ṣe ìrántí ìpele ìjọba-ayé ní ọdún 1965. Nínú ìránṣẹ́ rere tí agbẹnusọ fún Ilé-iṣẹ́ fún…
button