Browsing Category
ÌRÒYÌN ORÍLẸ̀-ÈDÈ NÀÍJIRÍÀ
This is a Nigeria news category
Olórí Ẹgbẹ́ Ọmọ-ogun Tún Jẹ́rìí sí Ààbò Àwọn Ọmọ-ogun
Olórí Ẹgbẹ́ Ọmọ-ogun, Lt. Gen. Waidi Shaibu, ti tún ṣé ìdánilójú pé ẹgbẹ́ ọmọ-ogun Nàìjíríà yóò máa ṣètìlẹ́yìn fún àwọn olórí àti àwọn ọmọ-ogun pẹ̀lú àwọn ètò ìlera tó yẹ, àwọn ohun èlò ìṣiṣẹ́ àti àtìlẹ́yìn àwọn olórí tó yẹ láti jẹ́ kí wọn…
Ìkọlù Àwọn Agbébọn Sí Ọfiisi Ọgbà Ìtọ́jú Ẹranko Àtijọ́: Makinde Ṣèlérí Òpin Sí Irú Ìkọlù Bẹẹ
Látàrí ìṣẹ̀lẹ̀ ìkọlù àwọn agbébọn sí àwọn òṣìṣẹ́ ọgbà ìtọ́jú ẹranko àtijọ ni Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí àwọn ènìyàn agbègbè náà láti ṣe sùúrù.
Ìṣẹ̀lẹ̀ ìkọlù àwọn agbébọn eléyìí ti Alukoro ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, DSP…
Sarkin Hausawa Ìlú Ìbàdàn Gbésẹ̀: Makinde Kẹ́dùn Pẹ̀lú Olúbàdàn Àti Ẹ̀yà Hausa Ní Ìlú Ìbàdàn
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti fi ikú Sarkin Hausawa ìlú Ìbàdàn, Alahji Ali Dahiru Zungeru we àdánù nla.
Gómìnà, ẹni tó fi olóògbé Zungeru wé olólùfẹ́ àlàáfíà àti adarí tó ṣeé gbẹ́kẹ̀lé náà ló bá Olúbàdàn ilẹ̀ Ìbàdàn,…
Ẹgbẹ́ Ọmọ Ológun Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà Tú Àṣírí Àwọn Oníṣẹ́ Láabi Ni Ìpínlẹ̀ Adamawa.
Ẹgbẹ́ Ọmọ Ológun Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti wọn n pé ni OPHK ti dènà ìwà ìbàjẹ́ ti yóò mú emi opolopo àwọn ènìyàn ló.
Ọwọ́ ba àwọn ènìyàn mẹjọ, ati àwọn odara meji miran ni inu ọjà Gamboru ni èyí tì wọn fẹ gbà Emi ara wọn ati àwọn ènìyàn…
Ẹgbẹ́ Ọmọ Ológun Orílẹ̀-èdè Ṣe Ìfilọ́lẹ̀ ìpàdé Fún Ìdanilẹ́ẹ̀kọ́ Odún 2026.
Ẹgbẹ́ Ọmọ Ológun Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti bẹ̀rẹ̀ ìpàdé fún Ìdanilẹ́ẹ̀kọ́ ti odún 2026 pẹ̀lú ètò ati ìlànà ẹ̀kọ́ ẹyi ti àjọ TRADOC ṣe agbáterù re.
Nígbà ti o n sọ̀rọ̀ níbi ayẹyẹ náà ọgá àgbà pátá fún ẹgbẹ́ Ọmọ Ológun Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà…
Ètò ìṣúná owó Ọdún 2026 Jẹ́ Àtìlẹ́yìn Nlá Fún Ààrẹ Tinubu: Mínísítà Fún Ọ̀rọ̀ Tó Ńlọ
Mínísítà fún ọ̀rọ̀ tó nlọ Alhaji Mohammed Idris so wí pè ẹ̀tọ̀ ìṣúná owó Ọdún 2026 jẹ ohun tí wọ́n fi ọgbọ́n àti làákàyè gbé kalẹ fún àtìlẹ́yìn ijoba Ààrẹ Tinubu.
Nínú ọ̀rọ̀ tó jáde láti ẹnu Mallam Rabiu Ibrahim to jẹ ìgbà Kejì pàtàkì…
Gómìnà Seyi Makinde Kéde Ìṣípò-rọpò Nínú Ìgbìmọ̀ Aláṣẹ Ìṣèjọba Rẹ̀, O Yan Akọ̀wé Ìjọba Tuntun.
Gómìnà Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, Seyi Makinde ti kede Ọ̀jọ̀gbọ́n Musibau Adetunji Babatunde gẹ́gẹ́ bíi Akọ̀wé tuntun fún ìjọba Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, lẹ́yìn tó yọ Ọ̀jọ̀gbọ́n Olanike Adeyemo tii ṣe akọ̀wé ìjọba tẹlẹ.
Eléyìí ló jẹyọ nínú àtẹ̀jáde láti ọwọ́…
Àwọn Ọmọ-ogun Ṣàfihàn Ẹní Tó Ń Ṣètò Ìpara-ẹni Láàrin Ìlú Ní Àríwá-Ìlà Oòrùn
Àwọn Ọmọ-ogun tó ń ṣiṣẹ́ ní Àríwá-Ìlà Oòrùn Nàìjíríà HADIN KAI (OPHK) tí fí Ọ́gbẹ́ni Shariff Umar hàn gẹ́gẹ́ bí ẹní tó ń ṣètò ìpara-ẹni láàrín ìlú pẹ̀lú ado olóró tó ṣẹ̀ṣẹ̀ wáyé, èyí tí àwọn Ológun náà tí gbìyànjú láti dúró.
Èyí ni…
Ààrẹ Tinubu Pàṣẹ Pé Kí Wọ́n Bẹ̀rẹ̀ Sí Máa Wá Àwọn Tó Ṣékọlù Kasuwan Daji
Ààrẹ Bola Ahmed Tinubu tí pàṣẹ fún Mínísítà fún ààbò, Olórí Àwọn Ológun, Àwọn Olórí Gbogbo Àwọn Ọmọ Ológun, Olórí Àwọn Ọlọ́pàá, àti Olùdarí Àgbà ti Ẹ̀ka Àwọn Iṣẹ́ Ìpínlẹ̀ (DSS) láti wá àwọn tó ṣe ìkọlù sí Kasuwan Daji kí wọ́n sì mú wọn ní…
Àwọn ọmọ ológun ti gba àwon ará ìlú tí wón jí gbé ní ìpínlẹ̀ Borno sílẹ̀
Àwọn ọmọ-ogun ti Operation HADIN KAI (OPHK) tún ti ṣe àṣeyọrí pàtàkì mììràn lẹ́nu iṣẹ́ wọn, nígbà tí wọ́n farabalẹ̀ kán lu àwọn oníjàgídíjàgan kan ní ìjọba ìbílẹ̀ Konduga, ti Ìpínlẹ̀ Borno, léèyí tí ó yọrí…